< Psalms 14 >

1 Fún adarí orin. Ti Dafidi. Aṣiwèrè wí nínú ọkàn rẹ̀ pé, “Ko sí Ọlọ́run.” Wọ́n díbàjẹ́, iṣẹ́ wọn sì burú; kò sí ẹnìkan tí yóò ṣe rere.
Dāvida dziesma. Dziedātāju vadonim. Ģeķi saka savā sirdī Dieva nav; tie ir samaitājušies un sagānījušies ar savu darbošanos, neviena nav, kas labu dara.
2 Olúwa sì bojú wolẹ̀ láti ọ̀run wá lórí àwọn ọmọ ènìyàn bóyá ó le rí ẹni tí òye yé, ẹnikẹ́ni tó ń wá Ọlọ́run.
Tas Kungs skatās no debesīm uz cilvēku bērniem, raudzīt, vai jel kas būtu prātīgs, kas meklē Dievu.
3 Gbogbo wọn sì ti yípadà, gbogbo wọn sì ti díbàjẹ́; kò sì ṣí ẹni tí ó ń ṣe rere, kò sí ẹnìkan.
Bet tie visi atkāpušies, visnotaļ smirdoši tapuši, neviena nav, kas labu dara, nav it neviena.
4 Ǹjẹ́ olùṣe búburú kò ha ní ìmọ̀? Àwọn tí ó ń pa ènìyàn mi jẹ bí ẹní jẹun; wọn kò sì ké pe Olúwa?
Vai tad nav nekādas atzīšanas tiem ļauna darītājiem, kas ēd manus ļaudis, tā kā ēd maizi, bet To Kungu tie nepiesauc?
5 Wọ́n wà níbẹ̀, tí a bò mọ́lẹ̀ pẹ̀lú ẹ̀rù, nítorí Ọlọ́run wà ní àwùjọ àwọn olódodo.
Tad tie bīdamies izbīstas, jo Dievs ir pie tās taisnās cilts.
6 Ẹ̀yin olùṣe búburú da èrò àwọn tálákà rú, ṣùgbọ́n Olúwa ni ààbò wọn.
Jūs nievājat nabaga padomu, bet Tas Kungs ir viņa patvērums.
7 Ìgbàlà àwọn Israẹli yóò ti Sioni wá! Nígbà tí Olúwa bá mú ìkólọ àwọn ènìyàn rẹ̀ padà, jẹ́ kí Jakọbu kí ó yọ̀, kí inú Israẹli kí ó dùn!
Ak! Kaut no Ciānas nāktu Israēla pestīšana! Kad Tas Kungs atkal atved Savus cietuma ļaudis, tad Jēkabs priecāsies un Israēls līksmosies.

< Psalms 14 >