< Psalms 14 >

1 Fún adarí orin. Ti Dafidi. Aṣiwèrè wí nínú ọkàn rẹ̀ pé, “Ko sí Ọlọ́run.” Wọ́n díbàjẹ́, iṣẹ́ wọn sì burú; kò sí ẹnìkan tí yóò ṣe rere.
Pour la fin, psaume de David.
2 Olúwa sì bojú wolẹ̀ láti ọ̀run wá lórí àwọn ọmọ ènìyàn bóyá ó le rí ẹni tí òye yé, ẹnikẹ́ni tó ń wá Ọlọ́run.
Le Seigneur, du haut du ciel, a jeté un regard sur les fils des hommes, pourvoir s’il en est un qui ait de l’intelligence, et qui cherche Dieu.
3 Gbogbo wọn sì ti yípadà, gbogbo wọn sì ti díbàjẹ́; kò sì ṣí ẹni tí ó ń ṣe rere, kò sí ẹnìkan.
Tous se sont détournés; tous ensemble sont devenus inutiles; il n’en est pas qui fasse le bien, il n’en est pas même un seul. Leur gosier est un sépulcre ouvert, ils trompaient avec leurs langues; le venin de l’aspic est sous leurs lèvres. Leur bouche est pleine de malédiction et d’amertume; leurs pieds courent avec rapidité pour verser le sang. La désolation et le malheur sont sur leurs voies; mais la voie de la paix, ils ne l’ont pas connue; la crainte de Dieu n’est pas devant leurs yeux.
4 Ǹjẹ́ olùṣe búburú kò ha ní ìmọ̀? Àwọn tí ó ń pa ènìyàn mi jẹ bí ẹní jẹun; wọn kò sì ké pe Olúwa?
Est-ce qu’ils ne connaîtront point tous ceux qui opèrent l’iniquité, qui dévorent mon peuple comme un morceau de pain?
5 Wọ́n wà níbẹ̀, tí a bò mọ́lẹ̀ pẹ̀lú ẹ̀rù, nítorí Ọlọ́run wà ní àwùjọ àwọn olódodo.
Ils n’ont pas invoqué le Seigneur, ils ont tremblé de frayeur là où n’était pas la crainte.
6 Ẹ̀yin olùṣe búburú da èrò àwọn tálákà rú, ṣùgbọ́n Olúwa ni ààbò wọn.
Parce que le Seigneur est avec la génération des justes, vous avez confondu les desseins du pauvre, parce que le Seigneur est son espérance.
7 Ìgbàlà àwọn Israẹli yóò ti Sioni wá! Nígbà tí Olúwa bá mú ìkólọ àwọn ènìyàn rẹ̀ padà, jẹ́ kí Jakọbu kí ó yọ̀, kí inú Israẹli kí ó dùn!
Qui fera sortir de Sion le salut d’Israël? Lorsque le Seigneur aura mis fin à la captivité de son peuple, Jacob tressaillira de joie et Israël sera dans l’allégresse.

< Psalms 14 >