< Psalms 14 >

1 Fún adarí orin. Ti Dafidi. Aṣiwèrè wí nínú ọkàn rẹ̀ pé, “Ko sí Ọlọ́run.” Wọ́n díbàjẹ́, iṣẹ́ wọn sì burú; kò sí ẹnìkan tí yóò ṣe rere.
За първият певец. Давидов псалом. Безумният рече в сърцето си: Няма Бог. Поквариха се; сториха развалени дела; Няма кой да прави добро.
2 Olúwa sì bojú wolẹ̀ láti ọ̀run wá lórí àwọn ọmọ ènìyàn bóyá ó le rí ẹni tí òye yé, ẹnikẹ́ni tó ń wá Ọlọ́run.
Господ надникна от небесата над човешките чада За да види има ли някой разумен, Който да търси Бога.
3 Gbogbo wọn sì ti yípadà, gbogbo wọn sì ti díbàjẹ́; kò sì ṣí ẹni tí ó ń ṣe rere, kò sí ẹnìkan.
Всички се отбиха от пътя, заедно се развратиха; Няма кой да прави добро, няма ни един.
4 Ǹjẹ́ olùṣe búburú kò ha ní ìmọ̀? Àwọn tí ó ń pa ènìyàn mi jẹ bí ẹní jẹun; wọn kò sì ké pe Olúwa?
Без разум ли са всички, които беззаконствуват, Които изпояждат людете ми както ядат хляб, И не призовават Господа?
5 Wọ́n wà níbẹ̀, tí a bò mọ́lẹ̀ pẹ̀lú ẹ̀rù, nítorí Ọlọ́run wà ní àwùjọ àwọn olódodo.
Тогава Ги нападна голям страх; Защото Бог е в поколението на праведните.
6 Ẹ̀yin olùṣe búburú da èrò àwọn tálákà rú, ṣùgbọ́n Olúwa ni ààbò wọn.
Посрамихте намеренията на бедния; Господ, обаче, му е прибежище.
7 Ìgbàlà àwọn Israẹli yóò ti Sioni wá! Nígbà tí Olúwa bá mú ìkólọ àwọn ènìyàn rẹ̀ padà, jẹ́ kí Jakọbu kí ó yọ̀, kí inú Israẹli kí ó dùn!
Дано дойде от Сион избавление на Израиля! Когато Господ върне своите люде от плен, Тогава ще се зарадва Яков, ще се развесели Израил.

< Psalms 14 >