< Psalms 137 >

1 Ní ẹ̀bá odò Babeli, níbẹ̀ ni àwa gbé jókòó àwa sì sọkún nígbà tí àwa rántí Sioni.
Při řekách Babylonských tam jsme sedávali, a plakávali, rozpomínajíce se na Sion.
2 Àwa fi dùùrù wa kọ́ sí orí igi wílò, tí ó wà láàrín rẹ̀.
Na vrbí v té zemi zavěšovali jsme citary své.
3 Nítorí pé níbẹ̀ ni àwọn tí ó kó wa ní ìgbèkùn béèrè orin lọ́wọ́ wa, àti àwọn tí ó ni wá lára béèrè ìdárayá; wọn wí pé, “Ẹ kọ orin Sioni kan fún wa!”
A když se tam dotazovali nás ti, kteříž nás zajali, na slova písničky, (ješto jsme zavěsili byli veselí), říkajíce: Zpívejte nám některou píseň Sionskou:
4 Àwa ó ti ṣe kọ orin Olúwa ní ilẹ̀ àjèjì
Kterakž bychom měli zpívati píseň Hospodinovu v zemi cizozemců?
5 Jerusalẹmu, bí èmi bá gbàgbé rẹ jẹ́ kí ọwọ́ ọ̀tún mi kí ó gbàgbé ìlò rẹ̀.
Jestliže se zapomenu na tebe, ó Jeruzaléme, zapomeniž i pravice má.
6 Bí èmi kò bá rántí rẹ, jẹ́ kí ahọ́n mi kí ó lẹ̀ mọ́ èrìgì mi; bí èmi kò bá fi Jerusalẹmu ṣáájú olórí ayọ̀ mi gbogbo.
Přilniž i jazyk můj k dásním mým, nebudu-li se rozpomínati na tebe, jestliže v samém Jeruzalémě nebudu míti svého největšího potěšení.
7 Olúwa rántí ọjọ́ Jerusalẹmu, lára àwọn ọmọ Edomu, àwọn ẹni tí ń wí pé, “Wó o palẹ̀, wó o palẹ̀ dé ìpìlẹ̀ rẹ̀!”
Rozpomeň se, Hospodine, na Idumejské, a na den Jeruzaléma, kteříž pravili: Rozbořte, rozbořte až do základů v něm.
8 Ìwọ, ọmọbìnrin Babeli, ẹni tí a ó parun; ìbùkún ni fún ẹni tí ó san án fún ọ bí ìwọ ti rò sí wa.
Ó dcero Babylonská, zkažena býti máš. Blahoslavený ten, kdož odplatí tobě za to, což jsi nám zlého učinila.
9 Ìbùkún ni fún ẹni tí ó mú ọmọ wẹ́wẹ́ rẹ tí ó sì fi wọ́n ṣán òkúta.
Blahoslavený, kdož pochytí dítky tvé a o skálu je rozrážeti bude.

< Psalms 137 >