< Psalms 136 >
1 Ẹ fi ọpẹ́ fún Olúwa nítorí tí ó ṣeun;
Ku yi godiya ga Ubangiji, gama nagari ne shi.
2 Ẹ fi ọpẹ́ fún Ọlọ́run àwọn ọlọ́run:
Ku yi godiya ga Allahn alloli.
3 Ẹ fi ọpẹ́ fún Olúwa àwọn olúwa,
Ku yi godiya ga Ubangijin iyayengiji.
4 Fún Òun nìkan tí ń ṣiṣẹ́ ìyanu ńlá;
Gare shi wanda shi kaɗai yake aikata abubuwan banmamaki,
5 Fún ẹni tí ó fi ọgbọ́n dá ọ̀run;
Wanda ta wurin ganewarsa ya yi sammai,
6 Fún ẹni tí ó tẹ́ ilẹ̀ lórí omi;
Wanda ya shimfiɗa duniya a kan ruwaye,
7 Fún ẹni tí ó dá àwọn ìmọ́lẹ̀ ńlá;
Wanda ya yi manyan haskoki,
8 Òòrùn láti jẹ ọba ọ̀sán;
Rana don tă yi mulkin yini,
9 Òṣùpá àti ìràwọ̀ láti jẹ ọba òru;
Wata da taurari kuma don su yi mulkin dare;
10 Fún ẹni tí ó kọlu Ejibiti lára àwọn àkọ́bí wọn;
Gare shi wanda ya kashe’ya’yan fari Masar
11 Ó sì mú Israẹli jáde kúrò láàrín wọn;
Ya kuma fitar da Isra’ila daga cikinsu
12 Pẹ̀lú ọwọ́ agbára àti apá nínà;
Da hannu mai ƙarfi da hannu mai iko;
13 Fún ẹni tí ó pín Òkun pupa ní ìyà;
Gare shi wanda ya raba Jan Teku biyu
14 Ó sì mú Israẹli kọjá láàrín rẹ̀
Ya kawo Isra’ila ta tsakiyarsa,
15 Ṣùgbọ́n ó bi Farao àti ogun rẹ̀ ṣubú nínú Òkun pupa;
Amma ya share Fir’auna da mayaƙansa cikin Jan Teku;
16 Fún ẹni tí ó sin àwọn ènìyàn rẹ̀ la aginjù já
Gare shi wanda ya bi da mutanensa cikin hamada,
17 Fún ẹni tí ó kọlu àwọn ọba ńlá;
Wanda ya buge manyan sarakuna,
18 Ó sì pa àwọn ọba olókìkí
Ya karkashe manyan sarakuna,
19 Sihoni, ọba àwọn ará Amori
Sihon sarkin Amoriyawa
Da kuma Og sarkin Bashan,
21 Ó sì fi ilẹ̀ wọn fún ni ní ìní,
Ya kuma ba da ƙasarsu gādo,
22 Ìní fún Israẹli, ìránṣẹ́ rẹ̀,
Gādo ga bawansa Isra’ila;
23 Ẹni tí ó rántí wa ní ìwà ìrẹ̀lẹ̀ wa;
Shi wanda ya tuna da mu cikin ƙasƙancinmu
24 Ó sì dá wa ní ìdè lọ́wọ́ àwọn ọ̀tá wa;
Ya kuma’yantar da mu daga abokan gābanmu,
25 Ẹni tí ó fi oúnjẹ fún àwọn ẹ̀dá gbogbo
Wanda kuma ke ba da abinci ga kowace halitta.
26 Ẹ fi ọpẹ́ fún Ọlọ́run ọ̀run;
Ku yi godiya ga Allah na sama.