< Psalms 136 >

1 Ẹ fi ọpẹ́ fún Olúwa nítorí tí ó ṣeun;
Célébrez l'Eternel, car il est bon; parce que sa miséricorde demeure à toujours.
2 Ẹ fi ọpẹ́ fún Ọlọ́run àwọn ọlọ́run:
Célébrez le Dieu des dieux; parce que sa miséricorde demeure à toujours.
3 Ẹ fi ọpẹ́ fún Olúwa àwọn olúwa,
Célébrez le Seigneur des Seigneurs; parce que sa bonté demeure à toujours.
4 Fún Òun nìkan tí ń ṣiṣẹ́ ìyanu ńlá;
Célébrez celui qui seul fait de grandes merveilles; parce que sa bonté demeure à toujours.
5 Fún ẹni tí ó fi ọgbọ́n dá ọ̀run;
Celui qui a fait avec intelligence les cieux; parce que sa bonté demeure à toujours;
6 Fún ẹni tí ó tẹ́ ilẹ̀ lórí omi;
Celui qui a étendu la terre sur les eaux; parce que sa bonté demeure à toujours;
7 Fún ẹni tí ó dá àwọn ìmọ́lẹ̀ ńlá;
Celui qui a fait les grands luminaires; parce que sa bonté demeure à toujours;
8 Òòrùn láti jẹ ọba ọ̀sán;
Le soleil pour dominer sur le jour; parce que sa bonté demeure à toujours;
9 Òṣùpá àti ìràwọ̀ láti jẹ ọba òru;
La lune et les étoiles pour avoir domination sur la nuit; parce que sa bonté demeure à toujours;
10 Fún ẹni tí ó kọlu Ejibiti lára àwọn àkọ́bí wọn;
Celui qui a frappé l'Egypte en leurs premiers-nés; parce que sa bonté demeure à toujours;
11 Ó sì mú Israẹli jáde kúrò láàrín wọn;
Et qui a fait sortir Israël du milieu d'eux; parce que sa bonté demeure à toujours.
12 Pẹ̀lú ọwọ́ agbára àti apá nínà;
Et cela avec main forte et bras étendu; parce que sa bonté demeure à toujours.
13 Fún ẹni tí ó pín Òkun pupa ní ìyà;
Il a fendu la mer Rouge en deux; parce que sa bonté demeure à toujours;
14 Ó sì mú Israẹli kọjá láàrín rẹ̀
Et a fait passer Israël par le milieu d'elle; parce que sa bonté demeure à toujours:
15 Ṣùgbọ́n ó bi Farao àti ogun rẹ̀ ṣubú nínú Òkun pupa;
Et a renversé Pharaon et son armée dans la mer Rouge; parce que sa bonté demeure à toujours.
16 Fún ẹni tí ó sin àwọn ènìyàn rẹ̀ la aginjù já
Il a conduit son peuple par le désert; parce que sa bonté demeure à toujours.
17 Fún ẹni tí ó kọlu àwọn ọba ńlá;
Il a frappé les grands Rois; parce que sa bonté demeure à toujours.
18 Ó sì pa àwọn ọba olókìkí
Et a tué les Rois magnifiques; parce que sa bonté demeure à toujours.
19 Sihoni, ọba àwọn ará Amori
[Savoir], Sihon Roi des Amorrhéens; parce que sa bonté demeure à toujours;
20 Àti Ogu, ọba Baṣani;
Et Hog Roi de Basan; parce que sa bonté demeure à toujours.
21 Ó sì fi ilẹ̀ wọn fún ni ní ìní,
Et a donné leur pays en héritage; parce que sa bonté demeure à toujours;
22 Ìní fún Israẹli, ìránṣẹ́ rẹ̀,
En héritage à Israël son serviteur; parce que sa bonté demeure à toujours.
23 Ẹni tí ó rántí wa ní ìwà ìrẹ̀lẹ̀ wa;
Et qui, lorsque nous étions fort abaissés, s'est souvenu de nous, parce que sa bonté demeure à toujours;
24 Ó sì dá wa ní ìdè lọ́wọ́ àwọn ọ̀tá wa;
Et nous a délivrés [de la main] de nos adversaires; parce que sa bonté demeure à toujours.
25 Ẹni tí ó fi oúnjẹ fún àwọn ẹ̀dá gbogbo
Et il donne la nourriture à toute chair; parce que sa bonté demeure à toujours.
26 Ẹ fi ọpẹ́ fún Ọlọ́run ọ̀run;
Célébrez le Dieu des cieux; parce que sa bonté demeure à toujours.

< Psalms 136 >