< Psalms 135 >

1 Ẹ yin Olúwa. Ẹ yin orúkọ Olúwa; ẹ yìn ín, ẹ̀yin ìránṣẹ́ Olúwa.
Goocai Jehova. Goocai rĩĩtwa rĩa Jehova; inyuĩ ndungata cia Jehova-rĩ, mũgoocei,
2 Ẹ̀yin tí ń dúró ní ilé Olúwa, nínú àgbàlá ilé Ọlọ́run wa.
inyuĩ mũtungataga thĩinĩ wa nyũmba ya Jehova, o inyuĩ mũrũgamaga nja-inĩ cia nyũmba ya Ngai witũ.
3 Ẹ yin Olúwa: nítorí tí Olúwa ṣeun; ẹ kọrin ìyìn sí orúkọ rẹ̀; nítorí tí ó dùn.
Goocai Jehova, nĩgũkorwo Jehova nĩ mwega; inai mũgooce rĩĩtwa rĩake, nĩgũkorwo nĩ rĩega.
4 Nítorí tí Olúwa ti yan Jakọbu fún ara rẹ̀; àní Israẹli fún ìṣúra ààyò rẹ̀.
Nĩgũkorwo Jehova nĩethuurĩire Jakubu atuĩke wake, agathuura Isiraeli atuĩke igai rĩake kĩũmbe.
5 Nítorí tí èmi mọ̀ pé Olúwa tóbi, àti pé Olúwa jù gbogbo òrìṣà lọ.
Niĩ nĩnjũũĩ atĩ Jehova nĩ mũnene, atĩ Mwathani witũ nĩ mũnene gũkĩra ngai ciothe.
6 Olúwa ṣe ohunkóhun tí ó wù ú, ní ọ̀run àti ní ayé, ní Òkun àti ní ọ̀gbun gbogbo.
Jehova ekaga ũrĩa wothe ekwenda, kũu igũrũ na gũkũ thĩ, o na kũu iria-inĩ o na kũrĩa guothe kũriku mũno.
7 Ó mú ìkùùkuu gòkè láti òpin ilẹ̀ wá: ó dá mọ̀nàmọ́ná fún òjò: ó ń mú afẹ́fẹ́ ti inú ilẹ̀ ìṣúra rẹ̀ wá.
Nĩwe ũtũmaga matu mambate kuuma ituri-inĩ cia thĩ; nĩwe ũtũmaga kũgĩe heni irehanĩte na mbura, na akarehe rũhuho kuuma mĩthithũ-inĩ yake.
8 Ẹni tí ó kọlu àwọn àkọ́bí Ejibiti, àti ti ènìyàn àti ti ẹranko.
Nĩwe waringire marigithathi ma Misiri, marigithathi ma andũ na ma nyamũ.
9 Ẹni tí ó rán iṣẹ́ àmì àti iṣẹ́ ìyanu sí àárín rẹ̀, ìwọ Ejibiti, sí ara Farao àti sí ara àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀ gbogbo.
Wee Misiri, nĩwe watũmire thĩinĩ waku kũringwo ciama na morirũ, agĩũkĩrĩra Firaũni na ndungata ciake ciothe.
10 Ẹni tí ó kọlu àwọn orílẹ̀-èdè púpọ̀, tí ó sì pa àwọn alágbára ọba.
Nĩwe waringire ndũrĩrĩ nyingĩ na akĩũraga athamaki maarĩ hinya:
11 Sihoni, ọba àwọn ará Amori, àti Ogu, ọba Baṣani, àti gbogbo ìjọba Kenaani:
nĩo Sihoni mũthamaki wa Aamori, na Ogu mũthamaki wa Bashani, o na athamaki othe a Kaanani;
12 Ó sì fi ilẹ̀ wọn fún ni ní ìní, ìní fún Israẹli, ènìyàn rẹ̀.
akĩheana bũrũri wao ũtuĩke igai, ũtuĩke igai kũrĩ andũ ake a Isiraeli.
13 Olúwa orúkọ rẹ dúró láéláé; ìrántí rẹ Olúwa, láti ìrandíran.
Rĩĩtwa rĩaku, Wee Jehova, rĩtũũraga nginya tene, ngumo yaku, Wee Jehova, ĩgakinyĩra njiarwa na njiarwa.
14 Nítorí tí Olúwa yóò ṣe ìdájọ́ àwọn ènìyàn rẹ̀, yóò sì ṣe ìyọ́nú sí àwọn ọmọ ọ̀dọ̀ rẹ̀.
Nĩgũkorwo Jehova nĩagaciirĩrĩra andũ ake, na aiguĩre ndungata ciake tha.
15 Fàdákà òun wúrà ni èrè àwọn aláìkọlà, iṣẹ́ ọwọ́ ènìyàn ni.
Mĩhianano ya ndũrĩrĩ ĩthondeketwo na betha na thahabu, o wĩra wa moko ma andũ.
16 Wọ́n ní ẹnu, ṣùgbọ́n wọn kò le sọ̀rọ̀; wọ́n ní ojú, ṣùgbọ́n wọn kò fi ríran.
Nĩĩrĩ tũnua, no ndĩaragia, nĩĩrĩ maitho, no ndĩonaga;
17 Wọ́n ní etí, ṣùgbọ́n wọn kò fi gbọ́rọ̀; bẹ́ẹ̀ ni kò si èémí kan ní ẹnu wọn.
nĩĩrĩ matũ, no ndĩiguaga, o na ndĩrĩ mĩhũmũ tũnua-inĩ twayo.
18 Àwọn tí ń ṣe wọ́n dàbí wọn: gẹ́gẹ́ bẹ́ẹ̀ ni olúkúlùkù ẹni tí ó gbẹ́kẹ̀ rẹ̀ lé wọn.
Andũ arĩa mamĩthondekaga makaahaana o tayo, na noguo arĩa othe mamĩĩhokaga makaahaana.
19 Ẹ̀yin ara ilé Israẹli, ẹ fi ìbùkún fún Olúwa, ẹ̀yin ará ilé Aaroni, fi ìbùkún fún Olúwa.
Inyuĩ nyũmba ya Isiraeli, goocai Jehova; Inyuĩ nyũmba ya Harũni, goocai Jehova;
20 Ẹ̀yin ará ilé Lefi, fi ìbùkún fún Olúwa; ẹ̀yin tí ó bẹ̀rù Olúwa, fi ìbùkún fún Olúwa.
Inyuĩ nyũmba ya Lawi, goocai Jehova; inyuĩ arĩa mũmwĩtigĩrĩte, goocai Jehova.
21 Olùbùkún ni Olúwa, láti Sioni wá, tí ń gbé Jerusalẹmu. Ẹ fi ìyìn fún Olúwa.
Jehova arogoocwo kuuma Zayuni, o we ũtũũraga kũu Jerusalemu. Goocai Jehova.

< Psalms 135 >