< Psalms 135 >

1 Ẹ yin Olúwa. Ẹ yin orúkọ Olúwa; ẹ yìn ín, ẹ̀yin ìránṣẹ́ Olúwa.
Angraeng loe saphaw oh. Angraeng ih ahmin to saphaw oh; nangcae Angraeng ih tamnanawk, anih to saphaw oh.
2 Ẹ̀yin tí ń dúró ní ilé Olúwa, nínú àgbàlá ilé Ọlọ́run wa.
Nangcae Angraeng imthung ah angdoe kaminawk, aicae Sithaw im longhma ah angdoe kaminawk, Angraeng to saphaw oh,
3 Ẹ yin Olúwa: nítorí tí Olúwa ṣeun; ẹ kọrin ìyìn sí orúkọ rẹ̀; nítorí tí ó dùn.
Angraeng loe hoih pongah, Angraeng to saphaw oh; anih ih ahmin saphawhaih laa to sah oh, to loe anghoe han koi hmuen ah oh.
4 Nítorí tí Olúwa ti yan Jakọbu fún ara rẹ̀; àní Israẹli fún ìṣúra ààyò rẹ̀.
Angraeng mah Jakob to angmah hanah qoih, Israel to angmah ih hmuen ah suek hanah a qoih.
5 Nítorí tí èmi mọ̀ pé Olúwa tóbi, àti pé Olúwa jù gbogbo òrìṣà lọ.
Angraeng loe len, aicae Sithaw loe sithawnawk boih pongah doeh len, tiah ka panoek.
6 Olúwa ṣe ohunkóhun tí ó wù ú, ní ọ̀run àti ní ayé, ní Òkun àti ní ọ̀gbun gbogbo.
Van hoi long, tuipuinawk hoi kathuk ahmuennawk boih ah, Angraeng mah a koeh baktiah hmuennawk to a sak.
7 Ó mú ìkùùkuu gòkè láti òpin ilẹ̀ wá: ó dá mọ̀nàmọ́ná fún òjò: ó ń mú afẹ́fẹ́ ti inú ilẹ̀ ìṣúra rẹ̀ wá.
Anih mah long boenghaih ahmuen hoiah tamai amzamsak moe, tangphrapuekhaih hoi khotui to a sak; anih mah hmuen patuhaih ahmuen hoiah takhi to tacawtsak.
8 Ẹni tí ó kọlu àwọn àkọ́bí Ejibiti, àti ti ènìyàn àti ti ẹranko.
Anih mah Izip prae ih tapen tangsuek kami hoi moinawk to hum pae boih.
9 Ẹni tí ó rán iṣẹ́ àmì àti iṣẹ́ ìyanu sí àárín rẹ̀, ìwọ Ejibiti, sí ara Farao àti sí ara àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀ gbogbo.
Aw Izip, nang thungah kaom Faro hoi anih ih tamnanawk boih nuiah, tanoekhaih hoi dawnrai hmuennawk to na patoh.
10 Ẹni tí ó kọlu àwọn orílẹ̀-èdè púpọ̀, tí ó sì pa àwọn alágbára ọba.
Pop parai prae kaminawk to na dueksak moe, thacak siangpahrangnawk to na hum;
11 Sihoni, ọba àwọn ará Amori, àti Ogu, ọba Baṣani, àti gbogbo ìjọba Kenaani:
Amor kaminawk ih siangpahrang Sihon, Bashan siangpahrang Og hoi siangpahrang mah uk ih Kanaan praenawk boih;
12 Ó sì fi ilẹ̀ wọn fún ni ní ìní, ìní fún Israẹli, ènìyàn rẹ̀.
nihcae ih prae to angmah ih kami Israelnawk hanah qawk ah a paek.
13 Olúwa orúkọ rẹ dúró láéláé; ìrántí rẹ Olúwa, láti ìrandíran.
Aw Angraeng, na hmin loe dungzan khoek to cak; Aw Angraeng, na panoekhaih doeh, adung boih khoek to om tih.
14 Nítorí tí Olúwa yóò ṣe ìdájọ́ àwọn ènìyàn rẹ̀, yóò sì ṣe ìyọ́nú sí àwọn ọmọ ọ̀dọ̀ rẹ̀.
Angraeng mah angmah ih kaminawk to lokcaek ueloe, a tamnanawk nuiah dawnpakhuemhaih tawn tih.
15 Fàdákà òun wúrà ni èrè àwọn aláìkọlà, iṣẹ́ ọwọ́ ènìyàn ni.
Sithaw panoek ai kaminawk mah bok o ih krangnawk loe, sui, kami ban hoi sakcop ih sui hoi sumkanglung rumram ah ni oh.
16 Wọ́n ní ẹnu, ṣùgbọ́n wọn kò le sọ̀rọ̀; wọ́n ní ojú, ṣùgbọ́n wọn kò fi ríran.
Nihcae loe pakha tawnh o, toe lok apae o thai ai; mik a tawnh o, toe hnu o thai ai;
17 Wọ́n ní etí, ṣùgbọ́n wọn kò fi gbọ́rọ̀; bẹ́ẹ̀ ni kò si èémí kan ní ẹnu wọn.
naa a tawnh o, toe thaih o thai ai; pakha thungah anghahhaih takhi om ai.
18 Àwọn tí ń ṣe wọ́n dàbí wọn: gẹ́gẹ́ bẹ́ẹ̀ ni olúkúlùkù ẹni tí ó gbẹ́kẹ̀ rẹ̀ lé wọn.
Krang sah kaminawk loe krang baktiah ni oh o, krang oephaih tawn kaminawk doeh krang hoiah ni anghmong o boih.
19 Ẹ̀yin ara ilé Israẹli, ẹ fi ìbùkún fún Olúwa, ẹ̀yin ará ilé Aaroni, fi ìbùkún fún Olúwa.
Aw Israel imthung takoh, Angraeng to tahamhoihaih paek oh; Aw Aaron imthung takoh, Angraeng to tahamhoihaih paek oh;
20 Ẹ̀yin ará ilé Lefi, fi ìbùkún fún Olúwa; ẹ̀yin tí ó bẹ̀rù Olúwa, fi ìbùkún fún Olúwa.
Aw Levi imthung takoh, Angraeng to tahamhoihaih paek oh; Angraeng zii kaminawk, Angraeng to tahamhoihaih paek oh.
21 Olùbùkún ni Olúwa, láti Sioni wá, tí ń gbé Jerusalẹmu. Ẹ fi ìyìn fún Olúwa.
Jerusalem vangpui ah kaom Angraeng loe Zion hoiah tahamhoihaih om nasoe. Angraeng to saphaw oh.

< Psalms 135 >