< Psalms 135 >

1 Ẹ yin Olúwa. Ẹ yin orúkọ Olúwa; ẹ yìn ín, ẹ̀yin ìránṣẹ́ Olúwa.
Dayegon ninyo si Jehova. Dayegon ninyo ang ngalan ni Jehova; Dayega siya, Oh kamong mga alagad ni Jehova,
2 Ẹ̀yin tí ń dúró ní ilé Olúwa, nínú àgbàlá ilé Ọlọ́run wa.
Kamo nga nanagtindog sa balay ni Jehova, Diha sa mga sawang sa balay sa atong Dios.
3 Ẹ yin Olúwa: nítorí tí Olúwa ṣeun; ẹ kọrin ìyìn sí orúkọ rẹ̀; nítorí tí ó dùn.
Dayegon ninyo si Jehova; kay si Jehova maayo man: Panag-awit ug mga pagdayeg sa iyang ngalan; kay kini maoy makalilipay.
4 Nítorí tí Olúwa ti yan Jakọbu fún ara rẹ̀; àní Israẹli fún ìṣúra ààyò rẹ̀.
Kay si Jehova nagpili kang Jacob alang sa iyang kaugalingon, Ug sa Israel alang sa iyang kaugalingon nga pagpanag-iya.
5 Nítorí tí èmi mọ̀ pé Olúwa tóbi, àti pé Olúwa jù gbogbo òrìṣà lọ.
Kay nasayud ako nga si Jehova daku man, Ug nga ang atong Ginoo labaw sa tanang mga dios.
6 Olúwa ṣe ohunkóhun tí ó wù ú, ní ọ̀run àti ní ayé, ní Òkun àti ní ọ̀gbun gbogbo.
Bisan unsa ang gikahimut-an ni Jehova, kini iyang gibuhat, Didto sa langit ug dinhi sa yuta, diha sa kadagatan ug sa tanang mga kahiladman;
7 Ó mú ìkùùkuu gòkè láti òpin ilẹ̀ wá: ó dá mọ̀nàmọ́ná fún òjò: ó ń mú afẹ́fẹ́ ti inú ilẹ̀ ìṣúra rẹ̀ wá.
Siya nga nagapasaka sa mga panganod gikan sa mga kinatumyan sa yuta; Siyan nga nagabuhat sa mga kilat alang sa ulan; Siya nga nagapagula sa hangin gikan sa ilang mga tipiganan;
8 Ẹni tí ó kọlu àwọn àkọ́bí Ejibiti, àti ti ènìyàn àti ti ẹranko.
Siya nga milaglag sa mga panganay sa Egipto, Sa tawo ug sa mananap;
9 Ẹni tí ó rán iṣẹ́ àmì àti iṣẹ́ ìyanu sí àárín rẹ̀, ìwọ Ejibiti, sí ara Farao àti sí ara àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀ gbogbo.
Siya nga nagpadala ug mga ilhanan ug mga katingalahan diha sa kinataliwad-an nimo, Oh Egipto, Sa ibabaw ni Faraon, ug sa ibabaw sa tanan niyang mga ulipon;
10 Ẹni tí ó kọlu àwọn orílẹ̀-èdè púpọ̀, tí ó sì pa àwọn alágbára ọba.
Siya nga milaglag sa daghang mga nasud, Ug mipatay sa mga gamhanang hari,
11 Sihoni, ọba àwọn ará Amori, àti Ogu, ọba Baṣani, àti gbogbo ìjọba Kenaani:
Kang Sihon, nga hari sa mga Amorehanon, Ug kang Og nga hari sa Basan, Ug sa tanang mga gingharian sa Canaan,
12 Ó sì fi ilẹ̀ wọn fún ni ní ìní, ìní fún Israẹli, ènìyàn rẹ̀.
Ug gihatag ang ilang yuta alang sa usa ka panulondon, Usa ka panulondon ngadto sa Israel nga iyang katawohan.
13 Olúwa orúkọ rẹ dúró láéláé; ìrántí rẹ Olúwa, láti ìrandíran.
Ang imong ngalan, Oh Jehova, nagapadayon sa walay katapusan; Ang imong halandumon nga ngalan, Oh Jehova, ngadto sa tanang mga kaliwatan.
14 Nítorí tí Olúwa yóò ṣe ìdájọ́ àwọn ènìyàn rẹ̀, yóò sì ṣe ìyọ́nú sí àwọn ọmọ ọ̀dọ̀ rẹ̀.
Kay si Jehova mohukom sa iyang katawohan, Ug magabasul sa iyang kaugalingon mahatungod sa iyang mga alagad.
15 Fàdákà òun wúrà ni èrè àwọn aláìkọlà, iṣẹ́ ọwọ́ ènìyàn ni.
Ang mga dios-dios sa mga nasud mga salapi ug bulawan, Ang buhat sa mga kamot sa mga tawo.
16 Wọ́n ní ẹnu, ṣùgbọ́n wọn kò le sọ̀rọ̀; wọ́n ní ojú, ṣùgbọ́n wọn kò fi ríran.
(Sila) adunay mga baba, apan (sila) dili makasulti; (Sila) adunay mga mata, apan (sila) dili makakita;
17 Wọ́n ní etí, ṣùgbọ́n wọn kò fi gbọ́rọ̀; bẹ́ẹ̀ ni kò si èémí kan ní ẹnu wọn.
(Sila) adunay mga igdulungog, apan dili (sila) makadungog; Ni adunay gininhawa sa ilang mga baba.
18 Àwọn tí ń ṣe wọ́n dàbí wọn: gẹ́gẹ́ bẹ́ẹ̀ ni olúkúlùkù ẹni tí ó gbẹ́kẹ̀ rẹ̀ lé wọn.
(Sila) nga nanagbuhat kanila, manghisama kanila; Oo, ang tagsatagsa nga mosalig kanila.
19 Ẹ̀yin ara ilé Israẹli, ẹ fi ìbùkún fún Olúwa, ẹ̀yin ará ilé Aaroni, fi ìbùkún fún Olúwa.
Oh panimalay sa Israel, dayegon ninyo si Jehova: Oh panimalay ni Aaron, dayegon ninyo si Jehova:
20 Ẹ̀yin ará ilé Lefi, fi ìbùkún fún Olúwa; ẹ̀yin tí ó bẹ̀rù Olúwa, fi ìbùkún fún Olúwa.
Oh panimalay ni Levi, dayegon ninyo si Jehova: Kamo nga may kahadlok kang Jehova, dayegon ninyo si Jehova.
21 Olùbùkún ni Olúwa, láti Sioni wá, tí ń gbé Jerusalẹmu. Ẹ fi ìyìn fún Olúwa.
Dalayegon si Jehova gikan sa Sion, Siya nga nagapuyo sa Jerusalem Dayegon ninyo si Jehova.

< Psalms 135 >