< Psalms 132 >

1 Orin fún ìgòkè. Olúwa, rántí Dafidi nínú gbogbo ìpọ́njú rẹ̀.
He waiata; he pikitanga. E Ihowa, maharatia a Rawiri, me ona mamaetanga ngakau katoa;
2 Ẹni tí ó ti búra fún Olúwa, tí ó sì ṣe ìlérí fún alágbára Jakọbu pé.
Tana oati ki a Ihowa, tana kupu taurangi ki te Mea Nui o Hakopa;
3 Nítòótọ́, èmi kì yóò wọ inú àgọ́ ilé mi lọ, bẹ́ẹ̀ èmi kì yóò gun orí àkéte mi.
E kore rawa ahau e tae ki toku whare e noho ai ahau, e eke ranei ki runga ki toku moenga;
4 Èmi kì yóò fi oorun fún ojú mi, tàbí òògbé fún ìpéǹpéjú mi,
E kore ahau e tuku i oku kanohi kia moe, i oku kamo kia nenewha;
5 títí èmi ó fi rí ibi fún Olúwa, ibùjókòó fún alágbára Jakọbu.
Kia kitea ra ano e ahau he wahi mo Ihowa, he nohoanga mo te Mea Nui o Hakopa.
6 Kíyèsi i, àwa gbúròó rẹ̀ ni Efrata: àwa rí i nínú oko ẹgàn náà.
Na i rangona e matou ki Eparata, i kitea ki nga mara o te ngahere.
7 Àwa ó lọ sínú àgọ́ rẹ̀: àwa ó máa sìn níbi àpótí ìtìsẹ̀ rẹ̀
Ka haere matou ki roto ki ona tapenakara; ka koropiko ki tona turanga waewae.
8 Olúwa, dìde sí ibi ìsinmi rẹ: ìwọ, àti àpótí agbára rẹ.
E ara, e Ihowa, ki tou okiokinga, a koe, me te aaka o tou kaha.
9 Kí a fi òdodo wọ àwọn àlùfáà rẹ: kí àwọn ènìyàn mímọ́ rẹ kí ó máa hó fún ayọ̀.
Kia whakakakahuria au tohunga ki te tika; kia hamama tau hunga tapu i te hari.
10 Nítorí tí Dafidi ìránṣẹ́ rẹ̀, má ṣe yí ojú ẹni òróró rẹ padà.
Whakaaro ki a Rawiri, ki tau pononga: kaua e whakapeaua atu te mata o tau i whakawahi ai.
11 Olúwa ti búra nítòótọ́ fún Dafidi, Òun kì yóò yípadà kúrò nínú rẹ̀, nínú irú-ọmọ inú rẹ ni èmi ó gbé kalẹ̀ sí orí ìtẹ́ rẹ.
Kua oati pono a Ihowa ki a Rawiri, e kore ia e tahuri ke i tena; Ka whakanohoia e ahau tetahi hua o tou kopu ki tou torona.
12 Bí àwọn ọmọ rẹ̀ yóò bá pa májẹ̀mú mi mọ́ àti ẹ̀rí mi tí èmi yóò kọ́ wọn, àwọn ọmọ wọn pẹ̀lú yóò jókòó lórí ìtẹ́ rẹ láéláé.
Ki te puritia e au tama taku kawenata, me taku whakaaturanga e ako ai ahau ki a ratou, ka noho ano a ratou tama ki tou torona ake ake.
13 Nítorí tí Olúwa ti yan Sioni: ó ti fẹ́ ẹ fún ibùjókòó rẹ̀.
Kua whiriwhiria hoki e Ihowa a Hiona; kua hiahiatia e ia hei nohoanga mona.
14 Èyí ni ibi ìsinmi mi láéláé: níhìn-ín ni èmi yóò máa gbé: nítorí tí mo fẹ́ ẹ.
Ko toku okiokinga tenei ake ake; ko konei ahau noho ai, kua hiahiatia hoki e ahau.
15 Èmi yóò bùkún oúnjẹ rẹ̀ púpọ̀púpọ̀: èmi yóò fi oúnjẹ tẹ́ àwọn tálákà rẹ̀ lọ́rùn.
Ka manaakitia rawatia e ahau tana kai; ka whakamakonatia e ahau ona rawakore ki te taro.
16 Èmi yóò sì fi ìgbàlà wọ àwọn àlùfáà rẹ̀: àwọn ènìyàn mímọ́ rẹ̀ yóò máa hó fún ayọ̀.
Ka whakakakahuria hoki e ahau ona tohunga ki te whakaoranga; a ka hamama tona hunga tapu i te hari.
17 Níbẹ̀ ni èmi yóò gbé mú ìwo Dafidi yọ̀, èmi ti ṣe ìlànà fìtílà kan fún ẹni òróró mi.
Ka meinga e ahau kia pihi ki reira te haona o Rawiri: kua whakapaia e ahau he rama mo taku i whakawahi ai.
18 Àwọn ọ̀tá rẹ̀ ni èmi yóò fi ìtìjú wọ̀: ṣùgbọ́n lára òun tìkára rẹ̀ ni adé yóò máa gbilẹ̀.
Ka whakakakahuria e ahau ona hoariri ki te whakama; a ka matomato tona karauna i runga i a ia.

< Psalms 132 >