< Psalms 132 >

1 Orin fún ìgòkè. Olúwa, rántí Dafidi nínú gbogbo ìpọ́njú rẹ̀.
LEUM GOD, nik kom mulkunulla David Ac ma upa nukewa el tuh mutangla.
2 Ẹni tí ó ti búra fún Olúwa, tí ó sì ṣe ìlérí fún alágbára Jakọbu pé.
LEUM GOD, esam ma el tuh wulela kac, Wulela ku su el oru nu sum, God Kulana lal Jacob:
3 Nítòótọ́, èmi kì yóò wọ inú àgọ́ ilé mi lọ, bẹ́ẹ̀ èmi kì yóò gun orí àkéte mi.
“Nga ac fah tia utyak nu in lohm sik, ku oan fin mwe oan kiuk,
4 Èmi kì yóò fi oorun fún ojú mi, tàbí òògbé fún ìpéǹpéjú mi,
Nga ac fah tia mongla ku motulla,
5 títí èmi ó fi rí ibi fún Olúwa, ibùjókòó fún alágbára Jakọbu.
Nwe ke na nga orala sie acn in muta lun LEUM GOD, Sie lohm sin God Kulana lal Jacob.”
6 Kíyèsi i, àwa gbúròó rẹ̀ ni Efrata: àwa rí i nínú oko ẹgàn náà.
In acn Ephrathah kut tuh lohng ke Tuptup in Wuleang, Ac kut tuh konauk in acn Jearim.
7 Àwa ó lọ sínú àgọ́ rẹ̀: àwa ó máa sìn níbi àpótí ìtìsẹ̀ rẹ̀
Ac kut fahk, “Lela kut in som nu in lohm sin LEUM GOD; Lela kut in alu ye mutun tron lal.”
8 Olúwa, dìde sí ibi ìsinmi rẹ: ìwọ, àti àpótí agbára rẹ.
LEUM GOD, fahsru nu ke Tempul uh, wi Tuptup in Wuleang Su akilenyen ku lom, Ac muta we nwe tok.
9 Kí a fi òdodo wọ àwọn àlùfáà rẹ: kí àwọn ènìyàn mímọ́ rẹ kí ó máa hó fún ayọ̀.
Lela mwet tol lom in oru ma suwohs pacl e nukewa; Lela mwet lom in sasa ke engan!
10 Nítorí tí Dafidi ìránṣẹ́ rẹ̀, má ṣe yí ojú ẹni òróró rẹ padà.
Kom orala sie wulela nu sel David, mwet kulansap lom; LEUM GOD, nikmet sisla tokosra se su kom sulela.
11 Olúwa ti búra nítòótọ́ fún Dafidi, Òun kì yóò yípadà kúrò nínú rẹ̀, nínú irú-ọmọ inú rẹ ni èmi ó gbé kalẹ̀ sí orí ìtẹ́ rẹ.
Kom tuh orala sie wulela ku nu sel David — Sie wulela ma kom fah tia sifil ekulla, su fahk: “Nga fah oru tuh sie sin wen nutum in tokosra, Ac el ac fah leum tukum.
12 Bí àwọn ọmọ rẹ̀ yóò bá pa májẹ̀mú mi mọ́ àti ẹ̀rí mi tí èmi yóò kọ́ wọn, àwọn ọmọ wọn pẹ̀lú yóò jókòó lórí ìtẹ́ rẹ láéláé.
Wen nutum fin pwaye insialos nu ke wuleang luk Ac nu ke ma sap luk su nga sang nu selos, Na wen natulos ac fah oayapa eis acn sum in tokosra nwe tok.”
13 Nítorí tí Olúwa ti yan Sioni: ó ti fẹ́ ẹ fún ibùjókòó rẹ̀.
LEUM GOD El sulela Zion; El lungse orala tuh in nien muta lal:
14 Èyí ni ibi ìsinmi mi láéláé: níhìn-ín ni èmi yóò máa gbé: nítorí tí mo fẹ́ ẹ.
“Pa inge nien muta luk nwe tok. Pa inge acn su nga lungse leum we.
15 Èmi yóò bùkún oúnjẹ rẹ̀ púpọ̀púpọ̀: èmi yóò fi oúnjẹ tẹ́ àwọn tálákà rẹ̀ lọ́rùn.
Nga fah akkasrupye Zion ke mwe enenu lal nukewa; Nga fah akkihpye mwet sukasrup lal ke mwe mongo.
16 Èmi yóò sì fi ìgbàlà wọ àwọn àlùfáà rẹ̀: àwọn ènìyàn mímọ́ rẹ̀ yóò máa hó fún ayọ̀.
Nga fah akinsewowoye mwet tol lal in ma nukewa elos oru, Ac mwet lal fah on ac sasa ke engan.
17 Níbẹ̀ ni èmi yóò gbé mú ìwo Dafidi yọ̀, èmi ti ṣe ìlànà fìtílà kan fún ẹni òróró mi.
In acn se inge nga fah oru tuh sie sin fita lal David elan sie tokosra fulat; In acn se inge nga fah akloesye pacl in leum lun tokosra se su nga sulela.
18 Àwọn ọ̀tá rẹ̀ ni èmi yóò fi ìtìjú wọ̀: ṣùgbọ́n lára òun tìkára rẹ̀ ni adé yóò máa gbilẹ̀.
Nga fah nokomla mwet lokoalok lal ke mwekin, A tokosrai lal fah kapkapak ac yokyokelik.”

< Psalms 132 >