< Psalms 132 >

1 Orin fún ìgòkè. Olúwa, rántí Dafidi nínú gbogbo ìpọ́njú rẹ̀.
Tangtlaeng Laa Aw BOEIPA David ham a phaep pah te boeih poek pah.
2 Ẹni tí ó ti búra fún Olúwa, tí ó sì ṣe ìlérí fún alágbára Jakọbu pé.
BOEIPA taengah a caeng tih Jakob samrhang taengah khaw a caeng coeng.
3 Nítòótọ́, èmi kì yóò wọ inú àgọ́ ilé mi lọ, bẹ́ẹ̀ èmi kì yóò gun orí àkéte mi.
Ka dap im khuila ka pawk pawt vetih ka soengca rhaenghmuen khaw ka paan mahpawh.
4 Èmi kì yóò fi oorun fún ojú mi, tàbí òògbé fún ìpéǹpéjú mi,
Ka mik te ih sak ham, ka mikkhu te ngam sak ham ka pae mahpawh.
5 títí èmi ó fi rí ibi fún Olúwa, ibùjókòó fún alágbára Jakọbu.
BOEIPA ham a hmuen neh Jakob kah samrhang ham tolhmuen ka hmuh duela.
6 Kíyèsi i, àwa gbúròó rẹ̀ ni Efrata: àwa rí i nínú oko ẹgàn náà.
Khohmuen duup ah m'hmuh te Epharath ah khaw n'yaak uh coeng.
7 Àwa ó lọ sínú àgọ́ rẹ̀: àwa ó máa sìn níbi àpótí ìtìsẹ̀ rẹ̀
A tolhmuen la cet uh sih lamtah a kho kah khotloeng taengah bawk uh sih.
8 Olúwa, dìde sí ibi ìsinmi rẹ: ìwọ, àti àpótí agbára rẹ.
Aw BOEIPA nang na duemnah neh na sarhi thingkawng taengah thoo lah.
9 Kí a fi òdodo wọ àwọn àlùfáà rẹ: kí àwọn ènìyàn mímọ́ rẹ kí ó máa hó fún ayọ̀.
Na khosoih rhoek loh duengnah bai uh saeh lamtah na hlangcim rhoek loh tamhoe uh saeh.
10 Nítorí tí Dafidi ìránṣẹ́ rẹ̀, má ṣe yí ojú ẹni òróró rẹ padà.
Na sal David ham tah na koelh kah maelhmai te na mangthuung tak moenih.
11 Olúwa ti búra nítòótọ́ fún Dafidi, Òun kì yóò yípadà kúrò nínú rẹ̀, nínú irú-ọmọ inú rẹ ni èmi ó gbé kalẹ̀ sí orí ìtẹ́ rẹ.
BOEIPA loh David taengah oltak la a caeng coeng. Na bungko thaihtae lamkah khaw te lamloh mael pawt vetih nang ham ngolkhoel soah kang khueh bitni.
12 Bí àwọn ọmọ rẹ̀ yóò bá pa májẹ̀mú mi mọ́ àti ẹ̀rí mi tí èmi yóò kọ́ wọn, àwọn ọmọ wọn pẹ̀lú yóò jókòó lórí ìtẹ́ rẹ láéláé.
Ka paipi neh amih ka tukkil ka olphong te na ca rhoek loh a ngaithuen uh atah a ca rhoek khaw na ngolkhoel dongah a yoeyah la ngol uh ni.
13 Nítorí tí Olúwa ti yan Sioni: ó ti fẹ́ ẹ fún ibùjókòó rẹ̀.
BOEIPA loh Zion te a coelh tih amah tolrhum la a sahnaih thil.
14 Èyí ni ibi ìsinmi mi láéláé: níhìn-ín ni èmi yóò máa gbé: nítorí tí mo fẹ́ ẹ.
Ka duemnah he ka sahnaih coeng dongah a yoeyah la pahoi ka ngol thil ni.
15 Èmi yóò bùkún oúnjẹ rẹ̀ púpọ̀púpọ̀: èmi yóò fi oúnjẹ tẹ́ àwọn tálákà rẹ̀ lọ́rùn.
A sakah te ka uem ka uem pah vetih a khuikah khodaeng rhoek te buh ka cung sak ni.
16 Èmi yóò sì fi ìgbàlà wọ àwọn àlùfáà rẹ̀: àwọn ènìyàn mímọ́ rẹ̀ yóò máa hó fún ayọ̀.
Te vaengah a khosoih rhoek te khangnah ka bai sak vetih a hlangcim rhoek loh tamhoe la tamhoe uh ni.
17 Níbẹ̀ ni èmi yóò gbé mú ìwo Dafidi yọ̀, èmi ti ṣe ìlànà fìtílà kan fún ẹni òróró mi.
David ham ki pahoi ka cawn sak vetih ka koelh ham hmaithoi ka tok pah ni.
18 Àwọn ọ̀tá rẹ̀ ni èmi yóò fi ìtìjú wọ̀: ṣùgbọ́n lára òun tìkára rẹ̀ ni adé yóò máa gbilẹ̀.
A thunkha rhoek te yahpohnah ka bai sak vetih anih te a rhuisam neh ka khooi sak ni.

< Psalms 132 >