< Psalms 132 >

1 Orin fún ìgòkè. Olúwa, rántí Dafidi nínú gbogbo ìpọ́njú rẹ̀.
Hina Gode! Da: ibidi amola ea se baligili nabasu, amo mae gogolema!
2 Ẹni tí ó ti búra fún Olúwa, tí ó sì ṣe ìlérí fún alágbára Jakọbu pé.
Hina Gode! Di da Ya: igobe ea Gode Bagadedafa. Da: ibidi ea Dima ilegele sia: i amo mae gogolema! E amane ilegele sia: i,
3 Nítòótọ́, èmi kì yóò wọ inú àgọ́ ilé mi lọ, bẹ́ẹ̀ èmi kì yóò gun orí àkéte mi.
“Na da na diasua hame masunu amola hame golamu, amola hele mae fili galeawane, Hina Gode (Ya: igobe ea Gode Bagadedafa) Ea: diasu gagumu.”
4 Èmi kì yóò fi oorun fún ojú mi, tàbí òògbé fún ìpéǹpéjú mi,
5 títí èmi ó fi rí ibi fún Olúwa, ibùjókòó fún alágbára Jakọbu.
6 Kíyèsi i, àwa gbúròó rẹ̀ ni Efrata: àwa rí i nínú oko ẹgàn náà.
Ninia da Bedeleheme moilaiga esaloba, Dia Gousa: su Sema Gagili ea hou nabi. Ninia da amo hogolala, Yialimi soge ganodini dialebe ba: i.
7 Àwa ó lọ sínú àgọ́ rẹ̀: àwa ó máa sìn níbi àpótí ìtìsẹ̀ rẹ̀
Ninia amane sia: i, “Ninia Hina Gode Ea diasuga afia: la: di. Ninia Ea Fisu midadi nodone sia: ne gadomusa: afia: la: di.
8 Olúwa, dìde sí ibi ìsinmi rẹ: ìwọ, àti àpótí agbára rẹ.
Hina Gode! Debolo diasuga misa! Amola Dia Gousa: su Sema Gagili da Dia gasa bagade hou dawa: digima: ne olelesuba: le, amo Dia gaguli misini, amogawi mae fisili, eso huluane esalalaloma!
9 Kí a fi òdodo wọ àwọn àlùfáà rẹ: kí àwọn ènìyàn mímọ́ rẹ kí ó máa hó fún ayọ̀.
Dia gobele salasu dunu da eso huluane moloidafa hou abula agoane salimu da defea. Dia fi dunu ilia hahawaneba: le gesami hea: mu da defea.
10 Nítorí tí Dafidi ìránṣẹ́ rẹ̀, má ṣe yí ojú ẹni òróró rẹ padà.
Di da Dia hawa: hamosu dunu Da: ibidi, ema ilegele sia: i dagoi. Amaiba: le, Dia ilegei hina bagade amo higale mae yolesima.
11 Olúwa ti búra nítòótọ́ fún Dafidi, Òun kì yóò yípadà kúrò nínú rẹ̀, nínú irú-ọmọ inú rẹ ni èmi ó gbé kalẹ̀ sí orí ìtẹ́ rẹ.
Di da Da: ibidima dafawanedafa ilegele sia: su hamoi, amola amo ilegele sia: i Di da hamedafa bugimu. Di amane ilegele sia: i, “Na da dia mano afae amo hina bagade hamomu, amola e da di bagia Isala: ili fi ouligilalumu.
12 Bí àwọn ọmọ rẹ̀ yóò bá pa májẹ̀mú mi mọ́ àti ẹ̀rí mi tí èmi yóò kọ́ wọn, àwọn ọmọ wọn pẹ̀lú yóò jókòó lórí ìtẹ́ rẹ láéláé.
Dia mano ilia Na gousa: su noga: le nabasea, amola Na hamoma: ne sia: i ilima i, amo nabawane hamosea, ilia mano amola da di bagia, eso huluane mae fisili, Isala: ili fi ouligilalumu.”
13 Nítorí tí Olúwa ti yan Sioni: ó ti fẹ́ ẹ fún ibùjókòó rẹ̀.
Hina Gode da Saione Moilai Bai Bagade amo ganodini E esaloma: ne, ilegei dagoi.
14 Èyí ni ibi ìsinmi mi láéláé: níhìn-ín ni èmi yóò máa gbé: nítorí tí mo fẹ́ ẹ.
E amane ilegele sia: i, “Na da Saione Moilai Bai Bagade amo ganodini eso huluane fifi ahoanumu. Na da amogawi Isala: ili fi ouligilalumu hanai galebe.
15 Èmi yóò bùkún oúnjẹ rẹ̀ púpọ̀púpọ̀: èmi yóò fi oúnjẹ tẹ́ àwọn tálákà rẹ̀ lọ́rùn.
Na da Saione fi dunu ilia esaloma: ne lamu liligi defele ilima imunu. Na da Saione Moilai Bai Bagadega esalebe hame gagui dunu, ilima sadima: ne ha: i manu imunu.
16 Èmi yóò sì fi ìgbàlà wọ àwọn àlùfáà rẹ̀: àwọn ènìyàn mímọ́ rẹ̀ yóò máa hó fún ayọ̀.
Na da Saione fi ilia gobele salasu dunu, ilia hamobe huluane amo ganodini, gaga: su hou abula agoane ilima imunu. Amola Saione fi dunu da hahawaneba: le, gesami hea: mu amola wele sia: mu.
17 Níbẹ̀ ni èmi yóò gbé mú ìwo Dafidi yọ̀, èmi ti ṣe ìlànà fìtílà kan fún ẹni òróró mi.
Goegawi, Na da Da: ibidi egaga fi Dunu afae amo Hina Bagadedafa hamomu. Amola Na da Na ilegei Hina Bagade Ea ouligisu hou noga: le gaga: mu.
18 Àwọn ọ̀tá rẹ̀ ni èmi yóò fi ìtìjú wọ̀: ṣùgbọ́n lára òun tìkára rẹ̀ ni adé yóò máa gbilẹ̀.
Na da Ea ha lai dunu amo gogosiama: ne hamomu. Be Ea ouligibi da bagade gaguiwane heda: mu.”

< Psalms 132 >