< Psalms 130 >

1 Orin fún ìgòkè. Láti inú ibú wá ni èmi ń ké pè é ọ́ Olúwa
Aw Bawipa, a dungnaak hun awhkawng nang a venawh khy nyng.
2 Olúwa, gbóhùn mi, jẹ́ kí etí rẹ kí o tẹ́ sílẹ̀ sí ohùn ẹ̀bẹ̀ mi.
Aw Bawipa, kak awi ve ngai law lah. Qeennaak thoeh doena na venawh kak khynaak benna nang haa keng law lah.
3 Olúwa, ìbá ṣe pé kí ìwọ máa sàmì ẹ̀ṣẹ̀, Olúwa, tá ni ìbá dúró.
Aw Bawipa, nang ing thawlhnaak khqi ve na khoem mai mantaw, Aw Bawipa, u nu ak dyi thai kaw?
4 Nítorí ìdáríjì wà lọ́dọ̀ rẹ, kí a lè máa bẹ̀rù rẹ.
Cehlai namah a venawh qeenkhaw ngainaak awm hy; cedawngawh kqih awm na awm hyk ti.
5 Èmi dúró de Olúwa, ọkàn mi dúró, àti nínú ọ̀rọ̀ rẹ ni èmi ń ṣe ìrètí.
Bawipa ce qeh nyng, ka hqingnaak ing qeh hy, ak awi awh kang ngaih-unaak ce awm hy.
6 Ọkàn mi dúró de Olúwa, ju àwọn tí ń ṣọ́nà òwúrọ̀ lọ, àní ju àwọn tí ń ṣọ́nà òwúrọ̀ lọ.
Qaltoengkhqi ing mymcang ami qehdam anglakawh, ka hqingnaak ing Bawipa lamtoen hy.
7 Israẹli, ìwọ ní ìrètí ní ti Olúwa: nítorí pé lọ́dọ̀ Olúwa ni àánú wà, àti lọ́dọ̀ rẹ̀ ni ọ̀pọ̀lọpọ̀ ìdáǹdè wà.
Aw Israel Bawipa awh nang ngaih-unaak ce ta lah, kawtih Bawipa awh amak dyt thai lungnaak ing thaawngnaak soep ce awm hy.
8 Òun ó sì dá Israẹli ní ìdè kúrò nínú ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀ gbogbo.
Amah ing Israelkhqi ce a thawlhnaakkhqi boeih awhkawng hul kaw.

< Psalms 130 >