< Psalms 13 >

1 Fún adarí orin. Saamu ti Dafidi. Yóò ti pẹ́ tó, Olúwa? Ìwọ o ha gbàgbé mi títí láé? Yóò tí pẹ́ tó tí ìwọ yóò máa fi ojú rẹ pamọ́ fún mi?
Przedniejszemu śpiewakowi pieśń Dawidowa. Dokądże Panie? Zapomniszże mię na wieki? dokądże ukrywać będziesz oblicza twego przedemną?
2 Yóò ti pẹ́ tó tí èmi ó máa bá èrò mi jà, àti ní ojoojúmọ́ ni èmi ń ní ìbànújẹ́ ní ọkàn mi? Yóò ti pẹ́ tó tí àwọn ọ̀tá mi yóò máa borí mi?
Dokądże się będę radził w duszy swojej, a trapił w sercu mojem przez cały dzień? Dokądże się będzie wywyższał nieprzyjaciel mój nademną?
3 Wò mí kí o sì dá mi lóhùn, Olúwa Ọlọ́run mi. Fi ìmọ́lẹ̀ fún ojú mi, kí èmi ó má sún oorun ikú.
Wejrzyjże, wysłuchaj mię, Panie, Boże mój! oświeć oczy me, bym snać nie zasnął w śmierci;
4 Ọ̀tá mi wí pé, “Èmi ti ṣẹ́gun rẹ̀,” àwọn ọ̀tá mi yóò yọ̀ tí mo bá ṣubú.
By snać nie rzekł nieprzyjaciel mój: Przemogłem go; ażeby się nieprzyjaciele moi nie rodowali, gdybym się zachwiał.
5 Ṣùgbọ́n mo gbẹ́kẹ̀lé ìfẹ́ rẹ tí kì í kùnà; ọkàn mi ń yọ̀ nínú ìgbàlà rẹ.
Ale ja w miłosierdziu twojem ufam: rozraduje się serce moje w zbawieniu twojem;
6 Èmi ó máa kọrin sí Olúwa, nítorí ó dára sí mi.
będę śpiewał Panu, że mi dał wiele dobrego.

< Psalms 13 >