< Psalms 13 >

1 Fún adarí orin. Saamu ti Dafidi. Yóò ti pẹ́ tó, Olúwa? Ìwọ o ha gbàgbé mi títí láé? Yóò tí pẹ́ tó tí ìwọ yóò máa fi ojú rẹ pamọ́ fún mi?
Thaburi ya Daudi Nĩ nginya rĩ, Wee Jehova? Ũgũtũũra ũriganĩirwo nĩ niĩ nginya tene? Nĩ nginya rĩ ũgũtũũra ũũhithĩte ũthiũ waku?
2 Yóò ti pẹ́ tó tí èmi ó máa bá èrò mi jà, àti ní ojoojúmọ́ ni èmi ń ní ìbànújẹ́ ní ọkàn mi? Yóò ti pẹ́ tó tí àwọn ọ̀tá mi yóò máa borí mi?
Nĩ nginya rĩ ngũtũũra ngianaga na meciiria makwa, na o mũthenya ngoragwo na ihooru ngoro-inĩ yakwa? Nĩ nginya rĩ thũ yakwa ĩgũtũũra ĩĩhootaga?
3 Wò mí kí o sì dá mi lóhùn, Olúwa Ọlọ́run mi. Fi ìmọ́lẹ̀ fún ojú mi, kí èmi ó má sún oorun ikú.
Wee Jehova, Ngai wakwa, ndora na ũnjookerie ũhoro. Tũma maitho makwa mone, nĩguo ndikae gũkoma toro wa gĩkuũ;
4 Ọ̀tá mi wí pé, “Èmi ti ṣẹ́gun rẹ̀,” àwọn ọ̀tá mi yóò yọ̀ tí mo bá ṣubú.
nĩguo thũ yakwa ndĩkoige atĩrĩ, “Nĩndĩmũhootete,” nao arĩa marĩ muku na niĩ magĩkenere kũgũa gwakwa.
5 Ṣùgbọ́n mo gbẹ́kẹ̀lé ìfẹ́ rẹ tí kì í kùnà; ọkàn mi ń yọ̀ nínú ìgbàlà rẹ.
No niĩ ndĩhokete wendo waku ũrĩa ũtathiraga; ngoro yakwa ĩkenagĩra ũhonokio waku.
6 Èmi ó máa kọrin sí Olúwa, nítorí ó dára sí mi.
Nĩngũinĩra Jehova, nĩgũkorwo nĩanjĩkĩte wega mũno.

< Psalms 13 >