< Psalms 129 >

1 Orin fún ìgòkè. “Ìgbà púpọ̀ ni wọ́n ti pọ́n mi lójú láti ìgbà èwe mi wá,” jẹ́ kí Israẹli kí ó wí nísinsin yìí;
Ɔsoroforo dwom. “Wɔahyɛ me so pii afi me mmofraase, ma Israel nka ɛ.
2 “Ìgbà púpọ̀ ni wọ́n ti pọ́n mi lójú láti ìgbà èwe mi wá; síbẹ̀ wọn kò tí ì borí mi.
“Wɔahyɛ me so pii afi me mmofraase, nanso wontumi nnii me so nkonim ɛ.
3 Àwọn awalẹ̀ walẹ̀ sí ẹ̀yìn mi: wọ́n sì la aporo wọn gígùn.
Fɛntɛmfo afɛntɛm mʼakyi ayɛ wɔn nkɔmoa atenten.
4 Olódodo ni Olúwa: ó ti ké okùn àwọn ènìyàn búburú kúrò.”
Nanso Awurade yɛ ɔtreneeni; watwitwa amumɔyɛfo hama afi me ho ama made me ho.”
5 Kí gbogbo àwọn tí ó kórìíra Sioni kí ó dààmú, kí wọn kí ó sì yí ẹ̀yìn padà.
Ma wɔn a wɔtan Sion nyinaa mfa animguase nsan wɔn akyi.
6 Kí wọn kí ó dàbí koríko orí ilẹ̀ tí ó gbẹ dànù kí ó tó dàgbàsókè,
Ma wɔnnyɛ sɛ sare a ɛwɔ ɔdan atifi, a ennyin na ɛhyew;
7 èyí tí olóko pípa kó kún ọwọ́ rẹ̀: bẹ́ẹ̀ ni ẹni tí ń di ìtí, kó kún apá rẹ̀.
na nnɔbaetwafo ntumi nnya biribi mfi mu nhyɛ ne nsa ma, na nea ɔboaboa ano nso nnya hwee nhyɛ nʼabasa ma.
8 Bẹ́ẹ̀ ni àwọn tí ń kọjá lọ kò wí pé, ìbùkún Olúwa kí ó pẹ̀lú yín: àwa ń súre fún yin ní orúkọ Olúwa.
Mma wɔn a wotwa mu wɔ hɔ no nka se, “Awurade nhyira mmra mo so; yehyira mo wɔ Awurade din mu.”

< Psalms 129 >