< Psalms 129 >

1 Orin fún ìgòkè. “Ìgbà púpọ̀ ni wọ́n ti pọ́n mi lójú láti ìgbà èwe mi wá,” jẹ́ kí Israẹli kí ó wí nísinsin yìí;
Thaburi ya Agendi Maanahinyĩrĩria mũno kuuma ũnini-inĩ wakwa, Isiraeli nĩmakiuge ũguo,
2 “Ìgbà púpọ̀ ni wọ́n ti pọ́n mi lójú láti ìgbà èwe mi wá; síbẹ̀ wọn kò tí ì borí mi.
maanahinyĩrĩria mũno kuuma ũnini-inĩ wakwa, no rĩrĩ, matirĩ maahota kũndooria.
3 Àwọn awalẹ̀ walẹ̀ sí ẹ̀yìn mi: wọ́n sì la aporo wọn gígùn.
Andũ arĩa marĩmaga na mũraũ marĩmĩte ngʼongʼo wakwa, magatema mĩtaro mĩraihu.
4 Olódodo ni Olúwa: ó ti ké okùn àwọn ènìyàn búburú kúrò.”
No rĩrĩ, Jehova nĩ mũthingu; nĩanjohorithĩtie harĩ mĩhĩndo ya andũ arĩa aaganu.
5 Kí gbogbo àwọn tí ó kórìíra Sioni kí ó dààmú, kí wọn kí ó sì yí ẹ̀yìn padà.
Andũ arĩa othe mathũire Zayuni marocookio na thuutha maconokete.
6 Kí wọn kí ó dàbí koríko orí ilẹ̀ tí ó gbẹ dànù kí ó tó dàgbàsókè,
Marohaana ta nyeki ĩrĩ nyũmba igũrũ, ĩrĩa ĩhoohaga ĩtanamera;
7 èyí tí olóko pípa kó kún ọwọ́ rẹ̀: bẹ́ẹ̀ ni ẹni tí ń di ìtí, kó kún apá rẹ̀.
mũmĩtui ndangĩmĩiyũria hĩ-inĩ ciake, o na kana ũrĩa ũmĩũnganagia amĩiyũrie moko-inĩ make.
8 Bẹ́ẹ̀ ni àwọn tí ń kọjá lọ kò wí pé, ìbùkún Olúwa kí ó pẹ̀lú yín: àwa ń súre fún yin ní orúkọ Olúwa.
Andũ arĩa mahĩtũkagĩra kuo maroaga kuuga atĩrĩ, “Kĩrathimo kĩa Jehova kĩrogĩa igũrũ rĩanyu; nĩtwamũrathima thĩinĩ wa rĩĩtwa rĩa Jehova.”

< Psalms 129 >