< Psalms 129 >

1 Orin fún ìgòkè. “Ìgbà púpọ̀ ni wọ́n ti pọ́n mi lójú láti ìgbà èwe mi wá,” jẹ́ kí Israẹli kí ó wí nísinsin yìí;
Kathutkung: Panuekhoeh, tami tangawn ni Hezekiah a ti awh Ka nawca hoiyah ahnimouh ni na rektap awh, telah Isarelnaw ni tet awh naseh.
2 “Ìgbà púpọ̀ ni wọ́n ti pọ́n mi lójú láti ìgbà èwe mi wá; síbẹ̀ wọn kò tí ì borí mi.
Ka nawca hoiyah ahnimouh ni kai teh, na rektap awh. Hatei, na tâ awh hoeh.
3 Àwọn awalẹ̀ walẹ̀ sí ẹ̀yìn mi: wọ́n sì la aporo wọn gígùn.
Ka hnukthun vah talai thawn e patetlah a thawn awh teh, laikong kasawlah a sak awh.
4 Olódodo ni Olúwa: ó ti ké okùn àwọn ènìyàn búburú kúrò.”
Hatei, BAWIPA teh a lan. Ahni ni tamikaponaw e tangronnaw teh, thouk thouk a bouk pouh.
5 Kí gbogbo àwọn tí ó kórìíra Sioni kí ó dààmú, kí wọn kí ó sì yí ẹ̀yìn padà.
Zion kahmuhmanaw pueng teh, kayak awh naseh, hnuklah ban awh naseh.
6 Kí wọn kí ó dàbí koríko orí ilẹ̀ tí ó gbẹ dànù kí ó tó dàgbàsókè,
Ahnimouh teh, a kung a len hoehnahlan remke e lemphu e phokung patetlah awm awh naseh.
7 èyí tí olóko pípa kó kún ọwọ́ rẹ̀: bẹ́ẹ̀ ni ẹni tí ń di ìtí, kó kún apá rẹ̀.
Hote pho teh, kaanaw hanelah, kut kasum khuem hai phat hoeh. Ka tangoungnaw hanelah, tapam khuem hai phat hoeh.
8 Bẹ́ẹ̀ ni àwọn tí ń kọjá lọ kò wí pé, ìbùkún Olúwa kí ó pẹ̀lú yín: àwa ń súre fún yin ní orúkọ Olúwa.
Ka cet kaawm pueng nihai, BAWIPA e yawhawi teh nangmouh koe awm lawiseh. Kaimouh ni BAWIPA min lahoi nangmouh yawhawi na poe awh telah a dei awh mahoeh.

< Psalms 129 >