< Psalms 126 >

1 Orin fún ìgòkè. Nígbà tí Olúwa mú ìkólọ Sioni padà, àwa dàbí ẹni tí ó ń lá àlá.
Pieśń stopni. Gdy zaś Pan nawrócił pojmanych z Syonu, byliśmy jako ci, którym się śni.
2 Nígbà náà ni ẹnu wa kún fún ẹ̀rín, àti ahọ́n wa kọ orin; nígbà náà ni wọ́n wí nínú àwọn kèfèrí pé, Olúwa ṣe ohun ńlá fún wọn.
Tedy były napełnione weselem usta nasze, a język nasz radością; tedy mówiono między narodami: Wielmożne rzeczy Pan uczynił z nimi.
3 Olúwa ṣe ohun ńlá fún wa; nítorí náà àwa ń yọ̀.
Wielmożne rzeczy Pan uczynił z nami, z czegośmy się bardzo uradowali.
4 Olúwa mú ìkólọ wa padà, bí ìṣàn omi ní gúúsù.
Przywróćże zaś, o Panie! pojmanie nasze, jako strumienie na południe.
5 Àwọn tí ń fi omijé fún irúgbìn yóò fi ayọ̀ ka.
Którzy siali ze łzami, żąć będą z wykrzykaniem;
6 Ẹni tí ń fi ẹkún rìn lọ, tí ó sì gbé irúgbìn lọ́wọ́, lóòtítọ́, yóò fi ayọ̀ padà wá, yóò sì ru ìtí rẹ̀.
Tam i sam chodząc z płaczem rozsiewa lud drogie nasienie; ale zaś przyszedłszy z radością znosić będzie snopy swoje.

< Psalms 126 >