< Psalms 126 >

1 Orin fún ìgòkè. Nígbà tí Olúwa mú ìkólọ Sioni padà, àwa dàbí ẹni tí ó ń lá àlá.
I A Iehova i hoihoi mai ai i ka pio ana o Ziona, Like no kakou me ka poe moe uhane.
2 Nígbà náà ni ẹnu wa kún fún ẹ̀rín, àti ahọ́n wa kọ orin; nígbà náà ni wọ́n wí nínú àwọn kèfèrí pé, Olúwa ṣe ohun ńlá fún wọn.
Alaila, piha no ko kakou waha i ka akaaka, A me ko kakou alelo i ka hauoli; Alaila, olelo no lakou iwaena o ko na aina e, Nani na mea a Iehova i hana mai ai no lakou la.
3 Olúwa ṣe ohun ńlá fún wa; nítorí náà àwa ń yọ̀.
Ua nani no na mea a Iehova i hana mai ai no kakou; A ua lealea kakou malaila.
4 Olúwa mú ìkólọ wa padà, bí ìṣàn omi ní gúúsù.
E Iehova, e hoihoi oe i ko makou pio ana, E like me na kahawai, ma ke kukuluhema.
5 Àwọn tí ń fi omijé fún irúgbìn yóò fi ayọ̀ ka.
O ka poe lulu me na waimaka, E hoiliili lakou me ka hauoli.
6 Ẹni tí ń fi ẹkún rìn lọ, tí ó sì gbé irúgbìn lọ́wọ́, lóòtítọ́, yóò fi ayọ̀ padà wá, yóò sì ru ìtí rẹ̀.
He oiaio, o ka mea hele, a uwe, I kona lawe ana i ka hua e lulu ai, He oiaio no, e hoi mai oia me ka hauoli, E amo pu ana i kona mau pua.

< Psalms 126 >