< Psalms 125 >
1 Orin fún ìgòkè. Àwọn tí ó gbẹ́kẹ̀lé Olúwa yóò dàbí òkè Sioni, tí a kò lè ṣí ní ìdí, bí kò ṣe pé ó dúró láéláé.
Andũ arĩa mehokete Jehova matariĩ ta Kĩrĩma gĩa Zayuni, kĩrĩa gĩtangĩenyenyeka, no gĩtũũraga nginya tene.
2 Bí òkè ńlá ti yí Jerusalẹmu ká, bẹ́ẹ̀ ni Olúwa yí ènìyàn ká láti ìsinsin yìí lọ àti títí láéláé.
O ta ũrĩa irĩma ithiũrũrũkĩirie Jerusalemu ũguo noguo Jehova athiũrũrũkagĩria andũ ake, kuuma rĩu nginya tene na tene.
3 Nítorí tí ọ̀pá àwọn ènìyàn búburú kì yóò bà lé ìpín àwọn olódodo; kí àwọn olódodo kí ó máa ba à fi ọwọ́ wọn lé ẹ̀ṣẹ̀.
Mũthĩgi wa andũ arĩa aaganu ndũgũtũũra wathanaga bũrũri ũrĩa ũgaĩirwo andũ arĩa athingu, nĩguo andũ acio athingu matikae gũtambũrũkia moko mao meeke ũũru.
4 Olúwa ṣe rere fún àwọn ẹni rere, àti fún àwọn tí àyà wọn dúró ṣinṣin.
Wee Jehova, andũ arĩa ega mekaga o maũndũ mega, o acio arũngĩrĩru ngoro.
5 Bí ó ṣe ti irú àwọn tí wọn yà sí ipa ọ̀nà wíwọ́ wọn; Olúwa yóò jẹ́ kí wọn lọ pẹ̀lú àwọn oníṣẹ́ ẹ̀ṣẹ̀. Ṣùgbọ́n àlàáfíà yóò wà lórí Israẹli.
No rĩrĩ, andũ arĩa maahũkaga makagera njĩra iria njogomu-rĩ, Jehova nĩakamaingatanĩria hamwe na arĩa mekaga ũũru. Isiraeli kũrogĩa thayũ.