< Psalms 124 >
1 Orin fún ìgòkè. Ti Dafidi. “Ìbá má ṣe pé Olúwa tí ó ti wà fún wa,” kí ni Israẹli kí ó máa wí nísinsin yìí;
Canción de las gradas: de David. Al no haber estado el SEÑOR por nosotros, diga ahora Israel:
2 ìbá má ṣe pé Olúwa tó wà ní tiwa, nígbà tí àwọn ènìyàn gbógun sí wa,
Al no haber estado el SEÑOR por nosotros, cuando se levantaron contra nosotros los hombres,
3 nígbà náà ni wọn ò bá gbé wà mì láààyè nígbà tí ìbínú wọn ru sí wa,
vivos nos habrían entonces tragado, cuando se encendió su furor contra nosotros.
4 nígbà náà ni omi wọ̀n-ọn-nì ìbá bò wá mọ́lẹ̀,
Entonces nos habrían inundado las aguas; sobre nuestra alma hubiera pasado el torrente;
5 nígbà náà ni agbéraga omi ìbá borí ọkàn wa.
hubieran entonces pasado sobre nuestra alma las aguas soberbias.
6 Olùbùkún ni Olúwa, tí kò fi wá fún wọ́n bí ohun ọdẹ fún eyín wọn.
Bendito el SEÑOR, que no nos dio por presa a sus dientes.
7 Ọkàn wa yọ bí ẹyẹ jáde kúrò nínú okùn apẹyẹ; okùn já àwa sì yọ.
Nuestra alma escapó cual ave del lazo de los cazadores; se quebró el lazo, y escapamos nosotros.
8 Ìrànlọ́wọ́ wa ń bẹ ní orúkọ Olúwa, tí ó dá ọ̀run òun ayé.
Nuestro socorro es en el Nombre del SEÑOR, que hizo el cielo y la tierra.