< Psalms 124 >

1 Orin fún ìgòkè. Ti Dafidi. “Ìbá má ṣe pé Olúwa tí ó ti wà fún wa,” kí ni Israẹli kí ó máa wí nísinsin yìí;
Un cántico para los peregrinos que van a Jerusalén. Un salmo de David. Si el Señor no hubiera estado para nosotros, ¿Qué habría pasado? Todo Israel diga:
2 ìbá má ṣe pé Olúwa tó wà ní tiwa, nígbà tí àwọn ènìyàn gbógun sí wa,
Si el Señor no hubiera estado para nosotros, ¿Que hubiera pasado cuando los pueblos nos atacaron?
3 nígbà náà ni wọn ò bá gbé wà mì láààyè nígbà tí ìbínú wọn ru sí wa,
Nos hubieran tragado vivos al encenderse su furor contra nosotros.
4 nígbà náà ni omi wọ̀n-ọn-nì ìbá bò wá mọ́lẹ̀,
Se hubieran precipitado como una inundación; nos habrían arrastrado por completo como una corriente torrencial.
5 nígbà náà ni agbéraga omi ìbá borí ọkàn wa.
Habrían pasado por encima de nosotros con fuerza como aguas furiosas, ahogándonos.
6 Olùbùkún ni Olúwa, tí kò fi wá fún wọ́n bí ohun ọdẹ fún eyín wọn.
Alaben al Señor, quién no nos entregó a ellos como presas para ser destruidos por sus dientes.
7 Ọkàn wa yọ bí ẹyẹ jáde kúrò nínú okùn apẹyẹ; okùn já àwa sì yọ.
Escapamos de ellos como pájaros huyendo del cazador. ¡La trampa se rompió y volamos lejos!
8 Ìrànlọ́wọ́ wa ń bẹ ní orúkọ Olúwa, tí ó dá ọ̀run òun ayé.
Nuestra ayuda viene del Señor, quien hizo los cielos y la tierra.

< Psalms 124 >