< Psalms 124 >

1 Orin fún ìgòkè. Ti Dafidi. “Ìbá má ṣe pé Olúwa tí ó ti wà fún wa,” kí ni Israẹli kí ó máa wí nísinsin yìí;
Ein Loblied im höhern Chor. Wo der HERR nicht bei uns wäre, so sage Israel,
2 ìbá má ṣe pé Olúwa tó wà ní tiwa, nígbà tí àwọn ènìyàn gbógun sí wa,
wo der HERR nicht bei uns wäre, wenn die Menschen sich wider uns setzen:
3 nígbà náà ni wọn ò bá gbé wà mì láààyè nígbà tí ìbínú wọn ru sí wa,
so verschlängen sie uns lebendig, wenn ihr Zorn über uns ergrimmte;
4 nígbà náà ni omi wọ̀n-ọn-nì ìbá bò wá mọ́lẹ̀,
so ersäufte uns Wasser, Ströme gingen über unsre Seele;
5 nígbà náà ni agbéraga omi ìbá borí ọkàn wa.
es gingen Wasser allzu hoch über unsre Seele.
6 Olùbùkún ni Olúwa, tí kò fi wá fún wọ́n bí ohun ọdẹ fún eyín wọn.
Gelobet sei der HERR, daß er uns nicht gibt zum Raub in ihre Zähne!
7 Ọkàn wa yọ bí ẹyẹ jáde kúrò nínú okùn apẹyẹ; okùn já àwa sì yọ.
Unsre Seele ist entronnen wie ein Vogel dem Stricke des Voglers; der Strick ist zerrissen, wir sind los.
8 Ìrànlọ́wọ́ wa ń bẹ ní orúkọ Olúwa, tí ó dá ọ̀run òun ayé.
Unsre Hilfe steht im Namen des HERRN, der Himmel und Erden gemacht hat.

< Psalms 124 >