< Psalms 124 >
1 Orin fún ìgòkè. Ti Dafidi. “Ìbá má ṣe pé Olúwa tí ó ti wà fún wa,” kí ni Israẹli kí ó máa wí nísinsin yìí;
You Israeli [people], [answer this question]: What [would have happened to us] if Yahweh had not been (helping/fighting for) us?
2 ìbá má ṣe pé Olúwa tó wà ní tiwa, nígbà tí àwọn ènìyàn gbógun sí wa,
When [our enemies] attacked us, if Yahweh had not been fighting for us,
3 nígbà náà ni wọn ò bá gbé wà mì láààyè nígbà tí ìbínú wọn ru sí wa,
we would have all been killed [IDM] because they were very angry with us!
4 nígbà náà ni omi wọ̀n-ọn-nì ìbá bò wá mọ́lẹ̀,
[They would have been like] [MET] a flood that swept/carried us away; [it would have been as though] the water would have covered us,
5 nígbà náà ni agbéraga omi ìbá borí ọkàn wa.
and we would [all] have drowned in the flood that was (raging/flowing very fast).
6 Olùbùkún ni Olúwa, tí kò fi wá fún wọ́n bí ohun ọdẹ fún eyín wọn.
[But] praise Yahweh, because he has not allowed our [enemies to destroy us] [like wild animals] [MET] tear apart [the creatures that they capture].
7 Ọkàn wa yọ bí ẹyẹ jáde kúrò nínú okùn apẹyẹ; okùn já àwa sì yọ.
We have escaped [from our enemies] like a bird escapes from the trap that hunters have set; [it is as though] the trap [that our enemies set for us] was broken and we have escaped from it!
8 Ìrànlọ́wọ́ wa ń bẹ ní orúkọ Olúwa, tí ó dá ọ̀run òun ayé.
Yahweh is the one who helps us [MTY]; he is the one who made heaven and the earth.