< Psalms 124 >
1 Orin fún ìgòkè. Ti Dafidi. “Ìbá má ṣe pé Olúwa tí ó ti wà fún wa,” kí ni Israẹli kí ó máa wí nísinsin yìí;
Hina Gode da ninimagale hame fidisu ganiaba, ninia da adi hamona: nobela: ? Isala: ili fi! Dabe adole ima!
2 ìbá má ṣe pé Olúwa tó wà ní tiwa, nígbà tí àwọn ènìyàn gbógun sí wa,
Nini ha lai dunu da ninima doagala: beba: le, Hina Gode da ninimagale hame gegei ganiaba, ninia ha lai dunu da ougi bagadeba: le, nini esalumuna: wane mogo sala: loba.
3 nígbà náà ni wọn ò bá gbé wà mì láààyè nígbà tí ìbínú wọn ru sí wa,
4 nígbà náà ni omi wọ̀n-ọn-nì ìbá bò wá mọ́lẹ̀,
Amola hano fili gala: le, nini mini ahoa: noba amola hano da nini dedebola: loba, nini da mogososone gela da: loba.
5 nígbà náà ni agbéraga omi ìbá borí ọkàn wa.
6 Olùbùkún ni Olúwa, tí kò fi wá fún wọ́n bí ohun ọdẹ fún eyín wọn.
Hina Gode da ninima ha lai dunuga nini gugunufinisisa: besa: le, Ilia logo hedofaiba: le, Ema nodomu da defea.
7 Ọkàn wa yọ bí ẹyẹ jáde kúrò nínú okùn apẹyẹ; okùn já àwa sì yọ.
Ninia da sio sanisu dunu ea sani amoga dasa: besa: le hobeasa, amo defele ninia hobea: i. Sani da gadelale sa: iba: le, ninia da halegale lala.
8 Ìrànlọ́wọ́ wa ń bẹ ní orúkọ Olúwa, tí ó dá ọ̀run òun ayé.
Nini fidisu da Hina Gode, mu amola osobo bagade hahamosu dunu, Emadini maha.