< Psalms 124 >

1 Orin fún ìgòkè. Ti Dafidi. “Ìbá má ṣe pé Olúwa tí ó ti wà fún wa,” kí ni Israẹli kí ó máa wí nísinsin yìí;
Davudun ziyarət nəğməsi. İndi İsrail söyləsin: Rəbb tərəfimizi saxlamasaydı,
2 ìbá má ṣe pé Olúwa tó wà ní tiwa, nígbà tí àwọn ènìyàn gbógun sí wa,
Bizə qarşı insanlar qalxarkən Rəbb tərəfimizi saxlamasaydı,
3 nígbà náà ni wọn ò bá gbé wà mì láààyè nígbà tí ìbínú wọn ru sí wa,
Bizə qarşı qəzəblərindən yanarkən Bizi diri-diri udardılar,
4 nígbà náà ni omi wọ̀n-ọn-nì ìbá bò wá mọ́lẹ̀,
Sular bizi yuyub-aparardı, Sellər üstümüzü basardı,
5 nígbà náà ni agbéraga omi ìbá borí ọkàn wa.
Azğın sular üstümüzü basardı.
6 Olùbùkún ni Olúwa, tí kò fi wá fún wọ́n bí ohun ọdẹ fún eyín wọn.
Alqış olsun Rəbbə! O bizi onların dişlərinə ov etmədi.
7 Ọkàn wa yọ bí ẹyẹ jáde kúrò nínú okùn apẹyẹ; okùn já àwa sì yọ.
Bizi ovçunun tələsindən bir quş kimi qurtardı, Tələ qırıldı, canımız azad oldu.
8 Ìrànlọ́wọ́ wa ń bẹ ní orúkọ Olúwa, tí ó dá ọ̀run òun ayé.
Bizə Rəbbin adından, Göyləri və yeri yaradandan yardım gəlir.

< Psalms 124 >