< Psalms 122 >
1 Orin fún ìgòkè. Ti Dafidi. Inú mi dùn nígbà tí wọ́n wí fún mi pé, “Ẹ jẹ́ kí á lọ sílé Olúwa.”
Thaburi ya Daudi Nĩndakenire hamwe na arĩa maanjĩĩrire atĩrĩ, “Nĩtũthiĩ nyũmba ya Jehova.”
2 Ẹsẹ̀ wa yóò dúró ní ẹnu ibodè rẹ, ìwọ Jerusalẹmu.
Magũrũ maitũ marũgamĩte ihingo-inĩ ciaku, wee Jerusalemu.
3 Jerusalẹmu, ìwọ tí a kọ́ bí ìlú tí o fi ara mọ́ra pọ̀ ṣọ̀kan.
Jerusalemu rĩakĩtwo ta itũũra inene rĩnyitithanĩtio wega.
4 Níbi tí àwọn ẹ̀yà máa ń gòkè lọ, àwọn ẹ̀yà Olúwa, ẹ̀rí fún Israẹli, láti máa dúpẹ́ fún orúkọ Olúwa.
Kũu nĩkuo mĩhĩrĩga yambataga, o yo mĩhĩrĩga ya Jehova, ĩgathiĩ kũgooca rĩĩtwa rĩa Jehova kũringana na mawatho marĩa aheete Isiraeli.
5 Nítorí ibẹ̀ ni a gbé ìtẹ́ ìdájọ́ kalẹ̀, àwọn ìtẹ́ ilé Dafidi.
Kũu nĩkuo kũigĩtwo itĩ cia ũnene cia atuanĩri ciira, o cio itĩ cia ũnene cia nyũmba ya Daudi.
6 Gbàdúrà fún àlàáfíà Jerusalẹmu; àwọn tí ó fẹ́ ọ yóò ṣe rere.
Hoerai Jerusalemu thayũ: “Arĩa makwendete marotũũra na thayũ.
7 Kí àlàáfíà kí ó wà nínú odi rẹ̀, àti ìre nínú ààfin rẹ̀.
Kũrĩa thingo ciaku ciirigĩire kũrogĩa na thayũ, naguo ũgitĩri ũgĩe ciikaro-inĩ ciaku cia ũthamaki.”
8 Nítorí àwọn ọkùnrin àti àwọn ẹgbẹ́ mi èmi yóò wí nísinsin yìí pé, kí àlàáfíà kí ó wà nínú rẹ̀.
Nĩ ũndũ wa ariũ a baba na arata, nguuga atĩrĩ, “Thayũ ũrogĩa thĩinĩ waku.”
9 Nítorí ilé Olúwa Ọlọ́run wa, èmi yóò máa wá ìre rẹ̀.
Nĩ ũndũ wa nyũmba ya Jehova Ngai witũ, caragia ũgaacĩru waku.