< Psalms 121 >

1 Orin fún ìgòkè. Èmi yóò gbé ojú mi sórí òkè wọ̀n-ọn-nì— níbo ni ìrànlọ́wọ́ mi yóò ti wá?
Ɔsoroforo dwom. Mema mʼani so kyerɛ mmepɔw no, ɛhe na me mmoa fi bɛba?
2 Ìrànlọ́wọ́ mi tí ọwọ́ Olúwa wá, ẹni tí ó dá ọ̀run òun ayé.
Me mmoa fi Awurade, ɔsoro ne asase yɛfo no.
3 Òun kì yóò jẹ́ kí ẹsẹ̀ rẹ kí ó yẹ̀; ẹni tí ó pa ọ́ mọ́ kì í tòògbé.
Ɔremma wo nan nwatiri, nea ɔhwɛ wo no rentɔ nko.
4 Kíyèsi, ẹni tí ń pa Israẹli mọ́, kì í tòògbé bẹ́ẹ̀ ni kì í sùn.
Ampa ara, nea ɔhwɛ Israel no rentɔ nko na ɔrenna.
5 Olúwa ni olùpamọ́ rẹ; Olúwa ní òjìji rẹ ní ọwọ́ ọ̀tún rẹ.
Awurade hwɛ wo so; Awurade ne wo nwini wɔ wo nsa nifa so;
6 Oòrùn kì yóò pa ọ́ ní ìgbà ọ̀sán tàbí òṣùpá ní ìgbà òru.
Owia rensɛe wo wɔ adekyee mu, na ɔsram nso rensɛe wo anadwo.
7 Olúwa yóò pa ọ́ mọ́ kúrò nínú ibi gbogbo yóò pa ọkàn rẹ mọ́
Awurade bɛbɔ wo ho ban afi ɔsɛe nyinaa ho, ɔbɛhwɛ wo nkwa so;
8 Olúwa yóò pa àlọ àti ààbọ̀ rẹ mọ́ láti ìgbà yìí lọ àti títí láéláé.
Awurade bɛhwɛ wʼadifi ne wo fieba so mprempren ne daa.

< Psalms 121 >