< Psalms 120 >

1 Orin fún ìgòkè. Èmi ké pe Olúwa nínú ìpọ́njú mi, ó sì dá mi lóhùn.
Rwiyo rworwendo. Ndinodana kuna Jehovha mukutambudzika kwangu, uye anondipindura.
2 Gbà mí, Olúwa, kúrò lọ́wọ́ ètè èké àti lọ́wọ́ ahọ́n ẹ̀tàn.
Haiwa Jehovha, ndiponesei pamiromo inoreva nhema, nendimi dzinonyengera.
3 Kí ni kí a fi fún ọ? Àti kí ni kí a túnṣe fún ọ, ìwọ ahọ́n ẹ̀tàn?
Achaiteiko kwauri, uye chimwe chiiko kunze kwezvizvi, iwe rurimi runonyengera?
4 Òun yóò bá ọ wí pẹ̀lú ọfà mímú ológun, pẹ̀lú ẹ̀yín iná igi ìgbálẹ̀.
Achakuranga nemiseve yakapinza yemhare, namazimbe anopfuta omuti womurara.
5 Ègbé ni fún mi tí èmi ṣe àtìpó ní Meṣeki, nítorí èmi gbé nínú àgọ́ ìlú Kedari!
Ndine nhamo ini ndinogara muMesheki, kuti ndinogara pakati pamatende eKedhari!
6 Ó ti pẹ́ tí èmi ti ń gbé láàrín àwọn tí ó kórìíra àlàáfíà.
Ndakagara nguva refu pakati pavanovenga rugare.
7 Ènìyàn àlàáfíà ni mí; ṣùgbọ́n nígbà tí mo bá sọ̀rọ̀, ogun ni dúró fun wọn.
Ndiri munhu worugare; asi pandinotaura, ivo ndevehondo.

< Psalms 120 >