< Psalms 120 >

1 Orin fún ìgòkè. Èmi ké pe Olúwa nínú ìpọ́njú mi, ó sì dá mi lóhùn.
Izaho niampoheke, le nikanjy Iehovà, vaho tinoi’e.
2 Gbà mí, Olúwa, kúrò lọ́wọ́ ètè èké àti lọ́wọ́ ahọ́n ẹ̀tàn.
O ry Iehovà, apitsoho an-tsoñin-dremborake ty fiaiko, boak’ ami’ty lela mamañahy.
3 Kí ni kí a fi fún ọ? Àti kí ni kí a túnṣe fún ọ, ìwọ ahọ́n ẹ̀tàn?
Inon-ty homeañ’ azo, ino ka ty hanoeñe ama’o ty lela letra’e tia?
4 Òun yóò bá ọ wí pẹ̀lú ọfà mímú ológun, pẹ̀lú ẹ̀yín iná igi ìgbálẹ̀.
ana-pale masiom-panalolahy, naho forohan’ andrabey!
5 Ègbé ni fún mi tí èmi ṣe àtìpó ní Meṣeki, nítorí èmi gbé nínú àgọ́ ìlú Kedari!
Hankàñe amako te mañialo e Mèseke añe, naho ty fimoneñako an-kiboho’ i Kedàre ao!
6 Ó ti pẹ́ tí èmi ti ń gbé láàrín àwọn tí ó kórìíra àlàáfíà.
Loho hatr’ela’e ty nitraofam-piaiko ami’ty kivoho’ o malaim-pilongoañeo.
7 Ènìyàn àlàáfíà ni mí; ṣùgbọ́n nígbà tí mo bá sọ̀rọ̀, ogun ni dúró fun wọn.
Toe mpitea filongoan-draho; fa ie ivolañako, aly avao ty onjone’ iereo.

< Psalms 120 >