< Psalms 120 >
1 Orin fún ìgòkè. Èmi ké pe Olúwa nínú ìpọ́njú mi, ó sì dá mi lóhùn.
Jeg raabte til Herren i min Nød, og han bønhørte mig.
2 Gbà mí, Olúwa, kúrò lọ́wọ́ ètè èké àti lọ́wọ́ ahọ́n ẹ̀tàn.
Herre! fri min Sjæl fra Løgnens Læbe, fra en svigefuld Tunge.
3 Kí ni kí a fi fún ọ? Àti kí ni kí a túnṣe fún ọ, ìwọ ahọ́n ẹ̀tàn?
Hvad giver han dig, og hvad giver han dig ydermere, du svigefulde Tunge?
4 Òun yóò bá ọ wí pẹ̀lú ọfà mímú ológun, pẹ̀lú ẹ̀yín iná igi ìgbálẹ̀.
Den vældiges skærpede Pile med Gløder af Enebærtræ!
5 Ègbé ni fún mi tí èmi ṣe àtìpó ní Meṣeki, nítorí èmi gbé nínú àgọ́ ìlú Kedari!
Ve mig! thi jeg har været som fremmed iblandt Mesek, jeg har boet ved Kedars Telte.
6 Ó ti pẹ́ tí èmi ti ń gbé láàrín àwọn tí ó kórìíra àlàáfíà.
Min Sjæl har længe nok boet hos dem, som hade Fred.
7 Ènìyàn àlàáfíà ni mí; ṣùgbọ́n nígbà tí mo bá sọ̀rọ̀, ogun ni dúró fun wọn.
Jeg er fredsommelig; men naar jeg taler, da ere disse færdige til Krig.