< Psalms 12 >
1 Fún adarí orin. Gẹ́gẹ́ bí ti ṣeminiti. Saamu ti Dafidi. Ràn wá lọ́wọ́, Olúwa, nítorí ẹni ìwà-bí-Ọlọ́run kò sí mọ́; olóòtítọ́ tí pòórá kúrò láàrín àwọn ènìyàn.
MAIN kom kotin jauaja, pwe me lelapok kan malaulaular, o me melel akan me malaulau ren aramaj akan.
2 Olúkúlùkù ń parọ́ fún aládùúgbò rẹ̀; ètè èké wọn ń sọ ẹ̀tàn.
Irail kin lokaia likam, amen amen on men impa, re lokaiaki lol riapot.
3 Kí Olúwa kí ó gé ètè èké wọn àti gbogbo ahọ́n ìfọ́nnu
Ieowa pan kotin ujada kil en au karoj me linkapin o lo, me kin lokaia wei ni aklapalap.
4 tí ó wí pé, “Àwa ó borí pẹ̀lú ahọ́n wa; àwa ní ètè wa, ta ni ọ̀gá wa?”
Me kin indinda: Lo atail, me kit pan pwai kida, o kil en au at me kit keleki; ij at kaun?
5 “Nítorí ìnilára àwọn aláìlágbára àti ìkérora àwọn aláìní, Èmi yóò dìde nísinsin yìí,” ni Olúwa wí. “Èmi yóò dáàbò bò wọ́n lọ́wọ́ àwọn tí ń ṣe àrankàn wọn.”
Ieowa kotin majani: I pan uda, pweki kankaneraner en me luet akan o janejan en me jamama kan: I pan jauaja i, me kin inon ion.
6 Ọ̀rọ̀ Olúwa sì jẹ aláìlábùkù, gẹ́gẹ́ bí fàdákà tí a yọ́ nínú ìléru amọ̀, tí a sọ di mímọ́ nígbà méje.
Majan en Ieowa me makelekeleta jilper, me kamakelekel kidar nan dal pwel en kijiniai pan pak iju.
7 Olúwa, ìwọ yóò pa wá mọ́ kí o sì gbà wá lọ́wọ́ àwọn ènìyàn wọ̀nyí títí láé.
Komui Main, pan kotin pera irail, o jinjila mon di wet kokolata.
8 Àwọn ènìyàn búburú ń rin ìrìn fáàrí kiri nígbà tí wọn ń bọ̀wọ̀ fún òsì láàrín àwọn ènìyàn.
Pwe me japun kan pan totolar waja karoj, ma aramaj jued pukat kin kaunda aramaj akan.