< Psalms 12 >

1 Fún adarí orin. Gẹ́gẹ́ bí ti ṣeminiti. Saamu ti Dafidi. Ràn wá lọ́wọ́, Olúwa, nítorí ẹni ìwà-bí-Ọlọ́run kò sí mọ́; olóòtítọ́ tí pòórá kúrò láàrín àwọn ènìyàn.
E KOKUA mai, e Iehova; no ka mea, ua oki ke kanaka lokomaikai; Ua pau hoi ka poe hoopono iwaena o na keiki a kanaka.
2 Olúkúlùkù ń parọ́ fún aládùúgbò rẹ̀; ètè èké wọn ń sọ ẹ̀tàn.
Ke kamailio nei kekahi i kekahi i ka mea lapuwale, Me na lehelehe malimali a me ka naau lua e olelo nei lakou.
3 Kí Olúwa kí ó gé ètè èké wọn àti gbogbo ahọ́n ìfọ́nnu
E oki ana no o Iehova i na lehelehe malimali a pau, A me ke alelo e haanui ana i na mea nui;
4 tí ó wí pé, “Àwa ó borí pẹ̀lú ahọ́n wa; àwa ní ètè wa, ta ni ọ̀gá wa?”
Ka i olelo iho, Me ko kakou alelo e lanakila ai kakou; No kakou no ko kakou mau lehelehe: Owai la ka Haku maluna o kakou?
5 “Nítorí ìnilára àwọn aláìlágbára àti ìkérora àwọn aláìní, Èmi yóò dìde nísinsin yìí,” ni Olúwa wí. “Èmi yóò dáàbò bò wọ́n lọ́wọ́ àwọn tí ń ṣe àrankàn wọn.”
No ka luhihewa ana o ka poe ilihune, No ka auwe ana o ka poe kaniuhu, E ku ai au iluna ano, wahi a Iehova, E hoonoho au ia ia i kahi ola, ke puhiia mai ia.
6 Ọ̀rọ̀ Olúwa sì jẹ aláìlábùkù, gẹ́gẹ́ bí fàdákà tí a yọ́ nínú ìléru amọ̀, tí a sọ di mímọ́ nígbà méje.
O na olelo a Iehova, he mau olelo maemae no ia, Me he kala la i hoaoia i ka umulepo, ehiku ka hoomaemae ana.
7 Olúwa, ìwọ yóò pa wá mọ́ kí o sì gbà wá lọ́wọ́ àwọn ènìyàn wọ̀nyí títí láé.
Nau no lakou e malama mai, e Iehova, Nau no lakou e hoola, mai keia hanauna aku a i ka manawa pau ole.
8 Àwọn ènìyàn búburú ń rin ìrìn fáàrí kiri nígbà tí wọn ń bọ̀wọ̀ fún òsì láàrín àwọn ènìyàn.
E hele ana no ka poe hewa i kela aoao a i keia aoao, I ka manawa i hookiekieia'i na kanaka ino loa.

< Psalms 12 >