< Psalms 12 >

1 Fún adarí orin. Gẹ́gẹ́ bí ti ṣeminiti. Saamu ti Dafidi. Ràn wá lọ́wọ́, Olúwa, nítorí ẹni ìwà-bí-Ọlọ́run kò sí mọ́; olóòtítọ́ tí pòórá kúrò láàrín àwọn ènìyàn.
Thaburi ya Daudi Jehova, tũteithie, nĩgũkorwo andũ arĩa etigĩri Ngai nĩmaniinĩtwo; andũ arĩa ehokeku nĩmathirĩte makoima gatagatĩ-inĩ ka andũ.
2 Olúkúlùkù ń parọ́ fún aládùúgbò rẹ̀; ètè èké wọn ń sọ ẹ̀tàn.
O mũndũ aheenagia mũndũ wa itũũra rĩake; mĩromo yao ya ũhinga yaragia maheeni.
3 Kí Olúwa kí ó gé ètè èké wọn àti gbogbo ahọ́n ìfọ́nnu
Jehova aroeheria mĩromo yothe ya ũhinga, o na nĩmĩ ciothe iria ciaragia na mwĩgaatho,
4 tí ó wí pé, “Àwa ó borí pẹ̀lú ahọ́n wa; àwa ní ètè wa, ta ni ọ̀gá wa?”
iria ciugaga atĩrĩ, “Tũkũhootana nĩ ũndũ wa nĩmĩ ciitũ; mĩromo ĩno tũrĩ nayo nĩ iitũ; mwathi witũ akĩrĩ ũ?”
5 “Nítorí ìnilára àwọn aláìlágbára àti ìkérora àwọn aláìní, Èmi yóò dìde nísinsin yìí,” ni Olúwa wí. “Èmi yóò dáàbò bò wọ́n lọ́wọ́ àwọn tí ń ṣe àrankàn wọn.”
“Tondũ wa kũhinyĩrĩrio kwa andũ arĩa matarĩ hinya, na gũcaaya kwa arĩa abatari-rĩ, rĩu nĩngwarahũka,” ũguo nĩguo Jehova ekuuga. “Nĩngũmagitĩra kuuma kũrĩ andũ arĩa mamacambagia.”
6 Ọ̀rọ̀ Olúwa sì jẹ aláìlábùkù, gẹ́gẹ́ bí fàdákà tí a yọ́ nínú ìléru amọ̀, tí a sọ di mímọ́ nígbà méje.
Nacio ciugo cia Jehova itirĩ mahĩtia, ihaana ta betha ĩthereirio kĩrugutĩro-inĩ kĩa rĩũmba, ĩtheretio maita mũgwanja.
7 Olúwa, ìwọ yóò pa wá mọ́ kí o sì gbà wá lọ́wọ́ àwọn ènìyàn wọ̀nyí títí láé.
Wee Jehova nĩũrĩtũmenyagĩrĩra wega, na ũtũgitagĩre kuuma kũrĩ andũ ta acio nginya tene.
8 Àwọn ènìyàn búburú ń rin ìrìn fáàrí kiri nígbà tí wọn ń bọ̀wọ̀ fún òsì láàrín àwọn ènìyàn.
Andũ arĩa aaganu macangacangaga marĩ na mwĩtĩĩo, rĩrĩa ũndũ ũrĩa mũũru ũragathĩrĩrio nĩ andũ.

< Psalms 12 >