< Psalms 116 >

1 Èmi fẹ́ràn Olúwa, nítorí ó gbọ́ ohùn mi; ó gbọ́ ẹkún mi fún àánú.
Ka lok hoi tahmen ka hnikhaih lok, anih mah ang thaih pae pongah, Angraeng to ka palung.
2 Nítorí ó yí etí rẹ̀ padà sí mi, èmi yóò máa pè é ni wọ́n ìgbà tí mo wà láààyè.
Kai khae bangah a naa to patueng pongah, ka hing thung anih to ka kawk han.
3 Okùn ikú yí mi ká, ìrora isà òkú wá sórí mi; ìyọnu àti ìbànújẹ́ borí mi. (Sheol h7585)
Kai loe duekhaih qui mah ang zaeng moe, taprong patangkhanghaih mah ang naeh; raihaih hoi palungsethaih to ka tongh. (Sheol h7585)
4 Nígbà náà ni mo ké pe orúkọ Olúwa: “Olúwa, èmi bẹ̀ ọ́, gba ọkàn mi!”
To naah Angraeng ih ahmin to ka kawk; Aw Angraeng, ka hinghaih na pahlong ah, tiah ka hnik.
5 Olúwa ní oore-ọ̀fẹ́, ó sì ní òdodo; Ọlọ́run wa kún fún àánú.
Angraeng loe toeng moe, tahmenhaih hoiah koi; ue, aicae ih Sithaw loe palungnathaih hoiah koi.
6 Olúwa pa àwọn ọlọ́kàn fífúyẹ́ mọ́ nígbà tí mo wà nínú àìní ńlá, ó gbà mí.
Angraeng mah poektoeng kami to khetzawn; poekhaih ka pahnaem naah, kai hae ang bomh.
7 Padà, ìwọ ọkàn mi, sí ibi ìsinmi rẹ, nítorí Olúwa ṣe dáradára sí ọ.
Aw ka hinghaih, nang hakhaih ahmuen ah amlaem ah; Angraeng mah nang hanah kahoih hmuen to sak boeh.
8 Nítorí ìwọ, Olúwa, ti gba ọkàn mi kúrò lọ́wọ́ ikú, ojú mi kúrò lọ́wọ́ omijé, àti ẹsẹ̀ mi kúrò lọ́wọ́ ìṣubú,
Duekhaih thung hoiah ka hinghaih hae pahlong ah, mikkhraetui krakhaih thung hoiah ka mik hae pahlong ah loe, amthaekhaih thung hoiah ka khoknawk to na pahlong rae ah.
9 nítorí èmi yóò máa rìn níwájú Olúwa ní ilẹ̀ alààyè.
Kai loe kahing kaminawk ih prae ah Angraeng hmaa ah ka caeh han.
10 Èmi gbàgbọ́; nítorí náà mo wí pé, “èmi rí ìpọ́njú púpọ̀”.
Kai loe patangkhang parai boeh, tiah ka thuih, toe tanghaih ka tawnh vop.
11 Àti nínú ìdààmú mi mo wí pé, “Èké ni gbogbo ènìyàn”.
Poek ai pui hoiah kaminawk loe lok amlai o boih, tiah ka thuih moeng boeh.
12 Kí ni èmi yóò san fún Olúwa nítorí gbogbo rere rẹ̀ sí mi?
Angraeng mah ka nuiah sak ih hoihaihnawk boih kawbangmaw ka pathok han?
13 Èmi yóò gbé ago ìgbàlà sókè èmi yóò sì máa ké pe orúkọ Olúwa.
Pahlonghaih boengloeng to ka patawnh moe, Angraeng ih ahmin to ka kawk han.
14 Èmi yóò mú ìlérí mi ṣẹ sí Olúwa ní ojú àwọn ènìyàn rẹ̀.
Angraeng khaeah lokkamhaih to anih ih kaminawk boih hmaa ah ka koepsak han.
15 Iyebíye ní ojú Olúwa àti ikú àwọn ẹni mímọ́ rẹ̀.
Angmah ih kaciim kaminawk duekhaih loe, Angraeng mikhnuk ah atho kaom koek ah oh.
16 Olúwa, nítòótọ́ ìránṣẹ́ rẹ ni mo jẹ́; èmi ni ìránṣẹ́ rẹ, ọmọ ìránṣẹ́bìnrin rẹ; ó ti tú mi sílẹ̀ nínú ìdè mi.
Aw Angraeng, kai loe na tamna tangtang ni; kai loe na tamna hoi na tamna nongpata ih capa ah ka oh; pathlethaih khawkqui to nang khramh pae.
17 Èmi yóò rú ẹbọ ọpẹ́ sí ọ èmi yóò sì ké pe orúkọ Olúwa.
Kawnhaih lok thuihaih to nang khaeah kang tathlang moe, Angraeng ih ahmin to ka kawk han.
18 Èmi yóò mú ìlérí mi sẹ sí Olúwa ní ojú gbogbo àwọn ènìyàn rẹ̀,
Angmah ih kaminawk boih hmaa ah Angraeng khaeah lokkamhaih to ka koepsak han,
19 nínú àgbàlá ilé Olúwa ní àárín rẹ̀, ìwọ Jerusalẹmu. Ẹ yin Olúwa.
Angraeng ih im longhmaa ah, Aw Jerusalem, nang salakah ka koepsak han. Angraeng to saphaw oh.

< Psalms 116 >