< Psalms 116 >

1 Èmi fẹ́ràn Olúwa, nítorí ó gbọ́ ohùn mi; ó gbọ́ ẹkún mi fún àánú.
Любя Господа, защото послуша Гласа ми и молбите ми;
2 Nítorí ó yí etí rẹ̀ padà sí mi, èmi yóò máa pè é ni wọ́n ìgbà tí mo wà láààyè.
Понеже приклони ухото Си към мене, Затова ще Го призовавам догдето съм жив.
3 Okùn ikú yí mi ká, ìrora isà òkú wá sórí mi; ìyọnu àti ìbànújẹ́ borí mi. (Sheol h7585)
Връзките на смъртта ме обвиха, И мъките на преизподнята ме намериха; Скръб и беда срещнах. (Sheol h7585)
4 Nígbà náà ni mo ké pe orúkọ Olúwa: “Olúwa, èmi bẹ̀ ọ́, gba ọkàn mi!”
Тогава призовах името Господно, и Го помолих; О Господи, избави душата ми.
5 Olúwa ní oore-ọ̀fẹ́, ó sì ní òdodo; Ọlọ́run wa kún fún àánú.
Благ е Господ и праведен, Да! милостив е нашият Бог.
6 Olúwa pa àwọn ọlọ́kàn fífúyẹ́ mọ́ nígbà tí mo wà nínú àìní ńlá, ó gbà mí.
Господ пази простодушните; В беда бях, и Той ме избави.
7 Padà, ìwọ ọkàn mi, sí ibi ìsinmi rẹ, nítorí Olúwa ṣe dáradára sí ọ.
Върни се, душе моя, в успокоението си, Защото Господ постъпи щедро към тебе.
8 Nítorí ìwọ, Olúwa, ti gba ọkàn mi kúrò lọ́wọ́ ikú, ojú mi kúrò lọ́wọ́ omijé, àti ẹsẹ̀ mi kúrò lọ́wọ́ ìṣubú,
Понеже си избавил душата ми от смърт, Очите ми от сълзи, и нозете ми от подхлъзване,
9 nítorí èmi yóò máa rìn níwájú Olúwa ní ilẹ̀ alààyè.
Затова ще ходя пред Господа в земята на живите.
10 Èmi gbàgbọ́; nítorí náà mo wí pé, “èmi rí ìpọ́njú púpọ̀”.
Аз повярвах, затова говорих; Много бях наскърбен.
11 Àti nínú ìdààmú mi mo wí pé, “Èké ni gbogbo ènìyàn”.
В тревогата си рекох: Всеки човек е измамлив.
12 Kí ni èmi yóò san fún Olúwa nítorí gbogbo rere rẹ̀ sí mi?
Що да въздам Господу За всичките Му благодеяния към мене?
13 Èmi yóò gbé ago ìgbàlà sókè èmi yóò sì máa ké pe orúkọ Olúwa.
Ще взема чашата на спасението, И ще призова името Господно;
14 Èmi yóò mú ìlérí mi ṣẹ sí Olúwa ní ojú àwọn ènìyàn rẹ̀.
Ще изпълня обреците си Господу, Да, пред всичките Му люде.
15 Iyebíye ní ojú Olúwa àti ikú àwọn ẹni mímọ́ rẹ̀.
Скъпоценна е пред Господа Смъртта на светиите Му.
16 Olúwa, nítòótọ́ ìránṣẹ́ rẹ ni mo jẹ́; èmi ni ìránṣẹ́ rẹ, ọmọ ìránṣẹ́bìnrin rẹ; ó ti tú mi sílẹ̀ nínú ìdè mi.
Ах! Господи, наистина аз съм Твой слуга; Твой слуга съм, син на Твоята слугиня; Ти си развързал връзките ми.
17 Èmi yóò rú ẹbọ ọpẹ́ sí ọ èmi yóò sì ké pe orúkọ Olúwa.
На Тебе ще принеса жертва на хваление, И името Господно ще призова.
18 Èmi yóò mú ìlérí mi sẹ sí Olúwa ní ojú gbogbo àwọn ènìyàn rẹ̀,
Ще изпълня облаците си Господу, Да! пред всичките Негови люде,
19 nínú àgbàlá ilé Olúwa ní àárín rẹ̀, ìwọ Jerusalẹmu. Ẹ yin Olúwa.
В дворовете на дома Господен, Всред тебе, Ерусалиме. Алилуя.

< Psalms 116 >