< Psalms 116 >
1 Èmi fẹ́ràn Olúwa, nítorí ó gbọ́ ohùn mi; ó gbọ́ ẹkún mi fún àánú.
Na da Hina Gode dogolegesa. Bai E da na sia: ne gadosu naba.
2 Nítorí ó yí etí rẹ̀ padà sí mi, èmi yóò máa pè é ni wọ́n ìgbà tí mo wà láààyè.
Na da eso huluane Ema wele sia: sea, E da na wele sia: su naba.
3 Okùn ikú yí mi ká, ìrora isà òkú wá sórí mi; ìyọnu àti ìbànújẹ́ borí mi. (Sheol )
Na da baligiliwane da: i dioi amola beda: i galu. Bai na bogole, bogoi uli dogoiga gudu sa: imu gadenene ba: i. (Sheol )
4 Nígbà náà ni mo ké pe orúkọ Olúwa: “Olúwa, èmi bẹ̀ ọ́, gba ọkàn mi!”
Amalalu, na da Hina Godema amane wele sia: i, “Hina Gode! Na Dima ha: giwane edegesa! Na gaga: ma!”
5 Olúwa ní oore-ọ̀fẹ́, ó sì ní òdodo; Ọlọ́run wa kún fún àánú.
Hina Gode Ea hou da noga: idafa, amola E da asigisa amola gogolema: ne olofosu dawa:
6 Olúwa pa àwọn ọlọ́kàn fífúyẹ́ mọ́ nígbà tí mo wà nínú àìní ńlá, ó gbà mí.
Hina Gode da gasa hamedei hahanibi dunu gaga: sa. Na bogomu se nabaloba, E da na gaga: i.
7 Padà, ìwọ ọkàn mi, sí ibi ìsinmi rẹ, nítorí Olúwa ṣe dáradára sí ọ.
Na da mae beda: iwane hahawane esalumu da defea. Bai Hina Gode da na noga: le fidi.
8 Nítorí ìwọ, Olúwa, ti gba ọkàn mi kúrò lọ́wọ́ ikú, ojú mi kúrò lọ́wọ́ omijé, àti ẹsẹ̀ mi kúrò lọ́wọ́ ìṣubú,
Hina Gode da na bogosa: besa: le, gaga: i. E da na si hano logo ga: i amola na ha lai amoga mae hasalasima: ne hamoi.
9 nítorí èmi yóò máa rìn níwájú Olúwa ní ilẹ̀ alààyè.
Amaiba: le, na da mae bogole, esaleawane, Hina Gode Ea midadi ahoa.
10 Èmi gbàgbọ́; nítorí náà mo wí pé, “èmi rí ìpọ́njú púpọ̀”.
11 Àti nínú ìdààmú mi mo wí pé, “Èké ni gbogbo ènìyàn”.
Na da musa: amane sia: i, “Na da gugunufinisi dagoi.” Na da beda: iba: le amane sia: i, “Dunu huluanedafa da ilima dafawane hamoma: beyale dawa: mu da hamedei.” Be amomane na da Hina Godema dafawaneyale dawa: lusu hame fisi.
12 Kí ni èmi yóò san fún Olúwa nítorí gbogbo rere rẹ̀ sí mi?
Hina Gode da nama hou ida: iwane hamonanebeba: le, na da Ema adi ima: bela: ?
13 Èmi yóò gbé ago ìgbàlà sókè èmi yóò sì máa ké pe orúkọ Olúwa.
E da na gaga: i dagoi. Amaiba: le, na Ema nodomusa: , waini hano iasu Ema imunusa: , gaguli misunu.
14 Èmi yóò mú ìlérí mi ṣẹ sí Olúwa ní ojú àwọn ènìyàn rẹ̀.
Na da Ema imunusa: ilegei liligi, amo dunu ilia gilisisu amo ganodini, Ema imunu.
15 Iyebíye ní ojú Olúwa àti ikú àwọn ẹni mímọ́ rẹ̀.
Hina Gode Ea fi dunu afae bogosea, Gode E da se bagade naba.
16 Olúwa, nítòótọ́ ìránṣẹ́ rẹ ni mo jẹ́; èmi ni ìránṣẹ́ rẹ, ọmọ ìránṣẹ́bìnrin rẹ; ó ti tú mi sílẹ̀ nínú ìdè mi.
Hina Gode! Na da Dia hawa: hamosu dunu. Na ame da Dima hawa: hamoi amo defele, na da Dima hawa: hamosa. Di da na mae bogoma: ne, gaga: i.
17 Èmi yóò rú ẹbọ ọpẹ́ sí ọ èmi yóò sì ké pe orúkọ Olúwa.
Na da Dima nodone gobele salimu, amola Dima nodone sia: ne gadomu.
18 Èmi yóò mú ìlérí mi sẹ sí Olúwa ní ojú gbogbo àwọn ènìyàn rẹ̀,
Dia dunu ilia gilisisu ganodini, Dia hadigi sogebi Yelusaleme Debolo diasu ganodini, na da Dima imunusa: ilegele sia: i liligi amo Dima imunu. Hina Godema nodoma!
19 nínú àgbàlá ilé Olúwa ní àárín rẹ̀, ìwọ Jerusalẹmu. Ẹ yin Olúwa.