< Psalms 115 >
1 Kì í ṣe fún wa, Olúwa kì í ṣe fún wa, ṣùgbọ́n fún orúkọ rẹ ni a fi ògo fún, fún àánú àti òtítọ́ rẹ.
Ti ithuĩ, Wee Jehova, ti ithuĩ twagĩrĩire kũgoocwo, no goocithia rĩĩtwa rĩaku, tondũ wa wendo na wĩhokeku waku.
2 Torí kí ni àwọn kèfèrí yóò ṣe sọ pé, níbo ni Ọlọ́run wa wà.
Nĩ kĩĩ gĩtũmaga ndũrĩrĩ ciũrie atĩrĩ, “Ngai wao akĩrĩ ha?”
3 Ṣùgbọ́n Ọlọ́run wa wà lọ́run: tí ó ń ṣe èyí tí ó wù ú.
Ngai witũ arĩ o igũrũ; we ekaga o ũrĩa endaga.
4 Fàdákà òun wúrà ni èrè àwọn aláìkọlà, iṣẹ́ ọwọ́ ènìyàn ni.
No mĩhianano yao nĩ betha na thahabu, wĩra ũthondeketwo na moko ma andũ.
5 Wọ́n ní ẹnu, ṣùgbọ́n wọn kò le sọ̀rọ̀, wọ́n ní ojú, ṣùgbọ́n wọn kò fi ríran.
Nĩĩrĩ tũnua, no ndĩaragia, nĩĩrĩ maitho, no ndĩonaga;
6 Wọ́n ní etí, ṣùgbọ́n wọn kò fi gbọ́rọ̀: wọ́n ní imú, ṣùgbọ́n wọn kò fi gbóòórùn.
nĩĩrĩ matũ, no ndĩiguaga, nĩĩrĩ na maniũrũ, no ndĩiguaga mũnungo;
7 Wọ́n ní ọwọ́, ṣùgbọ́n wọn kò lò ó, wọ́n ní ẹsẹ̀, ṣùgbọ́n wọn kò rìn; bẹ́ẹ̀ ni wọn kò sọ̀rọ̀ nínú òfin wọn.
nĩĩrĩ moko, no ndĩngĩhambata kĩndũ, nĩĩrĩ magũrũ, no ndĩngĩĩtwara; o na nĩĩrĩ mĩmero, no ndĩngĩnyuria.
8 Àwọn tí ń ṣe wọ́n dàbí wọn; gẹ́gẹ́ bẹ́ẹ̀ ni olúkúlùkù ẹni tí ó gbẹ́kẹ̀ rẹ̀ lé wọn.
Andũ arĩa mamĩthondekaga makaahaana o tayo, na noguo arĩa othe mamĩĩhokaga makaahaana.
9 Ìwọ Israẹli gbẹ́kẹ̀lé Olúwa: òun ni ìrànwọ́ àti ààbò wọn
Wee nyũmba ya Isiraeli, wĩhokage Jehova: we nĩwe ũteithio wao o na ngo yao.
10 Ẹ̀ yin ilé Aaroni, gbẹ́kẹ̀lé Olúwa: òun ni ìrànwọ́ àti ààbò wọn.
Wee nyũmba ya Harũni, wĩhokage Jehova: we nĩwe ũteithio wao o na ngo yao.
11 Ẹ̀ yin tí ó bẹ̀rù Olúwa, gbẹ́kẹ̀lé Olúwa: òun ní ìrànwọ́ àti ààbò wọn.
Inyuĩ arĩa mũmwĩtigĩrĩte, mwĩhokagei Jehova: we nĩwe ũteithio wao na ngo yao.
12 Olúwa tí ń ṣe ìrántí wa; yóò bùkún ilé Israẹli; yóò bùkún ilé Aaroni.
Jehova nĩatũririkanĩte na nĩegũtũrathima: Nĩekũrathima nyũmba ya Isiraeli, nĩekũrathima nyũmba ya Harũni,
13 Ìbùkún ni fún àwọn tí ó bẹ̀rù Olúwa, àti kékeré àti ńlá.
nĩekũrathima arĩa metigĩrĩte Jehova, anini na anene o ũndũ ũmwe.
14 Olúwa yóò mú ọ pọ̀ sí i síwájú àti síwájú, ìwọ àti àwọn ọmọ rẹ̀.
Jehova arotũma mũingĩhe, inyuĩ na ciana cianyu.
15 Ẹ fi ìbùkún fún Olúwa ẹni tí ó dá ọ̀run òun ayé.
Mũrorathimwo nĩ Jehova, Mũmbi wa igũrũ na thĩ.
16 Ọ̀run àní ọ̀run ni ti Olúwa: ṣùgbọ́n ayé ló fi fún ọmọ ènìyàn.
Kũu igũrũ mũno nĩ kwa Jehova, no thĩ nĩamĩheanĩte kũrĩ andũ.
17 Òkú kò lè yìn Olúwa, tàbí ẹni tí ó ti lọ sí ìsàlẹ̀ ìdákẹ́ jẹ́ẹ́.
Andũ arĩa akuũ matigoocaga Jehova, acio maikũrũkaga kũu ũkiri-inĩ;
18 Ṣùgbọ́n àwa ó fi ìbùkún fún Olúwa láti ìsinsin yìí lọ àti títí láéláé. Ẹ yin Olúwa.
nĩ ithuĩ tũrĩkumagia Jehova, kuuma rĩu nginya tene na tene. Goocai Jehova.