< Psalms 115 >
1 Kì í ṣe fún wa, Olúwa kì í ṣe fún wa, ṣùgbọ́n fún orúkọ rẹ ni a fi ògo fún, fún àánú àti òtítọ́ rẹ.
Hina Gode! Ninia da Dia hadigidafa hou amoma fawane nodomu da defea. Dunu da nini hadigi gala sia: mu da defea hame. Bai Di fawane da mae fisili, asigidafa hou hamonana, amola nini fisima: ne hame dawa:
2 Torí kí ni àwọn kèfèrí yóò ṣe sọ pé, níbo ni Ọlọ́run wa wà.
Fifi asi gala dunu da abuliba: le, “Dilia Gode da habila: ?” amane sia: sala: ?
3 Ṣùgbọ́n Ọlọ́run wa wà lọ́run: tí ó ń ṣe èyí tí ó wù ú.
Bai ninia Gode da Hebene ganodini esala. Amola E da Hi hanaiga fawane hamosa.
4 Fàdákà òun wúrà ni èrè àwọn aláìkọlà, iṣẹ́ ọwọ́ ènìyàn ni.
Eno fifi asi gala ilia ‘gode’ da silifa amola gouliga hamoi liligi, osobo bagade dunu ilia loboga hamoi fawane.
5 Wọ́n ní ẹnu, ṣùgbọ́n wọn kò le sọ̀rọ̀, wọ́n ní ojú, ṣùgbọ́n wọn kò fi ríran.
Ilia da lafi gala, be sia: baoumu hame dawa: Ilia da si gala, be ba: mu gogolesa.
6 Wọ́n ní etí, ṣùgbọ́n wọn kò fi gbọ́rọ̀: wọ́n ní imú, ṣùgbọ́n wọn kò fi gbóòórùn.
Ilia da ge gala be nabimu hamedei. Ilia da mi gala, be amoga gaha amola gabusiga: nabimu hamedei.
7 Wọ́n ní ọwọ́, ṣùgbọ́n wọn kò lò ó, wọ́n ní ẹsẹ̀, ṣùgbọ́n wọn kò rìn; bẹ́ẹ̀ ni wọn kò sọ̀rọ̀ nínú òfin wọn.
Ilia da lobo gala, be digili ba: mu hamedei. Ilia da emo gala be masunu gogolesa. Ilia da ouiya: le diala.
8 Àwọn tí ń ṣe wọ́n dàbí wọn; gẹ́gẹ́ bẹ́ẹ̀ ni olúkúlùkù ẹni tí ó gbẹ́kẹ̀ rẹ̀ lé wọn.
Dunu da amo loboga hamoi ogogosu ‘gode’ hahamoi amola ilima dafawaneyale dawa: sa, ilia da amo ogogosu liligi ilia hamoi, amo defele hamomu da defea.
9 Ìwọ Israẹli gbẹ́kẹ̀lé Olúwa: òun ni ìrànwọ́ àti ààbò wọn
Be dilia Isala: ili fi dunu! Hina Godema dafawaneyale dawa: ma! E da dili fidisa amola gaga: sa.
10 Ẹ̀ yin ilé Aaroni, gbẹ́kẹ̀lé Olúwa: òun ni ìrànwọ́ àti ààbò wọn.
Dilia Gode Ea gobele salasu dunu! Hina Godema dafawaneyale dawa: ma! E da dili fidisa amola gaga: sa.
11 Ẹ̀ yin tí ó bẹ̀rù Olúwa, gbẹ́kẹ̀lé Olúwa: òun ní ìrànwọ́ àti ààbò wọn.
Dilia Hina Godema nodone sia: ne gadolalebe dunu! Hina Godema dafawaneyale dawa: ma. E da dili fidisa amola gaga: sa.
12 Olúwa tí ń ṣe ìrántí wa; yóò bùkún ilé Israẹli; yóò bùkún ilé Aaroni.
Hina Gode da nini dawa: lala, amola ninima hahawane hou imunu. E da Isala: ili fi dunu amola Gode Ea gobele salasu dunu huluane Ilima hahawane imunu.
13 Ìbùkún ni fún àwọn tí ó bẹ̀rù Olúwa, àti kékeré àti ńlá.
E da dunu huluane, bagade amola fonobahadi defele, ilia da Ema nodone dawa: sea, ilima hahawane hou imunu.
14 Olúwa yóò mú ọ pọ̀ sí i síwájú àti síwájú, ìwọ àti àwọn ọmọ rẹ̀.
Hina Gode da dili amola diligaga fi dunuma mano imunu da defea.
15 Ẹ fi ìbùkún fún Olúwa ẹni tí ó dá ọ̀run òun ayé.
Hina Gode da mu amola osobo bagade hahamoi. E da dilima hahawane hou imunu da defea.
16 Ọ̀run àní ọ̀run ni ti Olúwa: ṣùgbọ́n ayé ló fi fún ọmọ ènìyàn.
Hebene da Hina Gode Ea Hisu soge. Be E da osobo bagade amo nini osobo bagade dunuma i dagoi.
17 Òkú kò lè yìn Olúwa, tàbí ẹni tí ó ti lọ sí ìsàlẹ̀ ìdákẹ́ jẹ́ẹ́.
Bogoi dunu ilia da ouiya: i soge amoga gudu daha. Bogoi dunu, ilia Hina Godema nodone sia: mu hamedei ba: sa.
18 Ṣùgbọ́n àwa ó fi ìbùkún fún Olúwa láti ìsinsin yìí lọ àti títí láéláé. Ẹ yin Olúwa.
Be nini esalebe dunu, ninia da Ema eso huluane mae fisili, nodonanumu. Hina Godema nodoma!