< Psalms 110 >
1 Ti Dafidi. Saamu. Olúwa sọ fún Olúwa mi pé, “Ìwọ jókòó ní ọwọ́ ọ̀tún mi, títí èmi yóò fi sọ àwọn ọ̀tá rẹ di àpótí ìtìsẹ̀ rẹ.”
Dāvida dziesma. Tas Kungs sacījis uz manu Kungu: “Sēdies pa Manu labo roku, tiekams Es Tavus ienaidniekus lieku par pameslu Tavām kājām.”
2 Olúwa yóò na ọ̀pá agbára rẹ̀ láti Sioni wá, ìwọ jẹ ọba láàrín àwọn ọ̀tá rẹ.
Tas Kungs sūtīs Tava stipruma scepteri no Ciānas; valdi Savu ienaidnieku vidū.
3 Àwọn ènìyàn rẹ jẹ́ ọ̀rẹ́ àtinúwá ní ọjọ́ ìjáde ogun rẹ, nínú ẹwà mímọ́, láti inú òwúrọ̀ wá ìwọ ni ìrì ẹwà rẹ.
Tavā kara dienā Tavi ļaudis labprātīgi parādās svētā glītumā; Tavi jaunekļi Tev nāk kā rasa no ausekļa.
4 Olúwa ti búra, kò sì í yí ọkàn padà pé, “Ìwọ ni àlùfáà, ní ipasẹ̀ Melkisedeki.”
Tas Kungs ir zvērējis un Tam nebūs žēl: “Tu esi priesteris mūžīgi pēc Melhizedeka kārtas.”
5 Olúwa, ọwọ́ ọ̀tún rẹ̀ ni yóò lu àwọn ọba bolẹ̀ ni ọjọ́ ìbínú rẹ̀.
Tas Kungs pie Tavas labās rokas satrieks ķēniņus Savas dusmības dienā.
6 Yóò ṣe ìdájọ́ láàrín kèfèrí, yóò kún ibùgbé wọn pẹ̀lú òkú ara; yóò fọ́n àwọn olórí ká sí orí ilẹ̀ ayé tí ó gbòòrò.
Viņš turēs tiesu pagānu starpā; Viņš piepildīs zemi ar miroņiem. Viņš satrieks to, kas ir galva pār lielu zemi.
7 Yóò mu nínú odò ṣíṣàn ní ọ̀nà: nítorí náà ni yóò ṣe gbé orí sókè.
Viņš dzers no upes uz ceļa, tādēļ Viņš pacels galvu.