< Psalms 110 >

1 Ti Dafidi. Saamu. Olúwa sọ fún Olúwa mi pé, “Ìwọ jókòó ní ọwọ́ ọ̀tún mi, títí èmi yóò fi sọ àwọn ọ̀tá rẹ di àpótí ìtìsẹ̀ rẹ.”
Thaburi ya Daudi Jehova nĩerire Mwathani wakwa atĩrĩ: “Ikara guoko-inĩ gwakwa kwa ũrĩo, nginya rĩrĩa ngaatũma thũ ciaku ituĩke gaturwa ka makinya maku.”
2 Olúwa yóò na ọ̀pá agbára rẹ̀ láti Sioni wá, ìwọ jẹ ọba láàrín àwọn ọ̀tá rẹ.
Mũthĩgi wa hinya waku-rĩ, Jehova nĩakaũtambũrũkia kuuma Zayuni; nĩũgaathana ũrĩ gatagatĩ ga thũ ciaku.
3 Àwọn ènìyàn rẹ jẹ́ ọ̀rẹ́ àtinúwá ní ọjọ́ ìjáde ogun rẹ, nínú ẹwà mímọ́, láti inú òwúrọ̀ wá ìwọ ni ìrì ẹwà rẹ.
Ikundi ciaku cia ita nĩikerutĩra mũthenya waku wa mbaara. Igooka irĩ na ũgemu wa ũtheru, aanake aku mahaana ta ime rĩoima nda ya rũciinĩ ruoro rũgĩtema.
4 Olúwa ti búra, kò sì í yí ọkàn padà pé, “Ìwọ ni àlùfáà, ní ipasẹ̀ Melkisedeki.”
Jehova nĩehĩtĩte na ndangĩĩricũkwo, akoiga atĩrĩ: “Wee ũrĩ mũthĩnjĩri-Ngai nginya tene, o ta ũrĩa Melikisedeki aatariĩ.”
5 Olúwa, ọwọ́ ọ̀tún rẹ̀ ni yóò lu àwọn ọba bolẹ̀ ni ọjọ́ ìbínú rẹ̀.
Mwathani arĩ guoko-inĩ gwaku kwa ũrĩo; nĩakahehenja athamaki mũthenya wa mangʼũrĩ make.
6 Yóò ṣe ìdájọ́ láàrín kèfèrí, yóò kún ibùgbé wọn pẹ̀lú òkú ara; yóò fọ́n àwọn olórí ká sí orí ilẹ̀ ayé tí ó gbòòrò.
Nĩagatuĩra ndũrĩrĩ ciira, aige ciimba irũndo, na ahehenje aathani a thĩ yothe.
7 Yóò mu nínú odò ṣíṣàn ní ọ̀nà: nítorí náà ni yóò ṣe gbé orí sókè.
Nĩakanyua maaĩ ma karũũĩ karĩ mũkĩra-inĩ; nĩ ũndũ ũcio nĩakambararia mũtwe wake.

< Psalms 110 >