< Psalms 110 >

1 Ti Dafidi. Saamu. Olúwa sọ fún Olúwa mi pé, “Ìwọ jókòó ní ọwọ́ ọ̀tún mi, títí èmi yóò fi sọ àwọn ọ̀tá rẹ di àpótí ìtìsẹ̀ rẹ.”
Bawipa ing Ka Bawipa a venawh: “Na qaalkhqi ce na khaw tloengnaak na ka sai hlan dy kak tang benawh ngawi lah,” tina hy.
2 Olúwa yóò na ọ̀pá agbára rẹ̀ láti Sioni wá, ìwọ jẹ ọba láàrín àwọn ọ̀tá rẹ.
Bawipa ing nang a sawnghqawl thakawm ce Zion awhkawng hul law kawmsaw, na qaalkhqing lak awh nang ing uk kawp ti.
3 Àwọn ènìyàn rẹ jẹ́ ọ̀rẹ́ àtinúwá ní ọjọ́ ìjáde ogun rẹ, nínú ẹwà mímọ́, láti inú òwúrọ̀ wá ìwọ ni ìrì ẹwà rẹ.
Na qalkapkhqi ing na qaal tuknaak khawnghi ce ngaih kawm uh. Ak ciim qypawmnaak ing thoeihcam qu nawh; mymcang phoen khui awhkawng ak thoeng law dam tui amyihna thak awm thym ce hu kawp ti.
4 Olúwa ti búra, kò sì í yí ọkàn padà pé, “Ìwọ ni àlùfáà, ní ipasẹ̀ Melkisedeki.”
Bawipa ing awi a sa hawh a dawngawh am thaw voel kaw: “Melkhizadek amyihna nang taw kumqui khawsoeih na awm hyk ti,” tihy.
5 Olúwa, ọwọ́ ọ̀tún rẹ̀ ni yóò lu àwọn ọba bolẹ̀ ni ọjọ́ ìbínú rẹ̀.
Bawipa taw nak tang ben awh awm nawh; ak kaw a sonaak nyn awh sangpahrangkhqi ce tun kqai khqi boeih kaw.
6 Yóò ṣe ìdájọ́ láàrín kèfèrí, yóò kún ibùgbé wọn pẹ̀lú òkú ara; yóò fọ́n àwọn olórí ká sí orí ilẹ̀ ayé tí ó gbòòrò.
Anih ing phynlum awideng kawmsaw, thlang a qawk ce a qawn kyng coengawh khawmdek pum awhkaw a lukhqi ce phep khqi kaw.
7 Yóò mu nínú odò ṣíṣàn ní ọ̀nà: nítorí náà ni yóò ṣe gbé orí sókè.
Lamkeng awhkaw lawngca tui ce aw kawmsaw, a lu ce hak zoek kaw.

< Psalms 110 >