< Psalms 110 >
1 Ti Dafidi. Saamu. Olúwa sọ fún Olúwa mi pé, “Ìwọ jókòó ní ọwọ́ ọ̀tún mi, títí èmi yóò fi sọ àwọn ọ̀tá rẹ di àpótí ìtìsẹ̀ rẹ.”
Hina Gode da na Hina Godema amane sia: i, “Na lobodafadili fili, amogai esaleawane, Na da Dia ha lai dunu da Dia emoga osa: laligima: ne hasalasimu.
2 Olúwa yóò na ọ̀pá agbára rẹ̀ láti Sioni wá, ìwọ jẹ ọba láàrín àwọn ọ̀tá rẹ.
Saione Goumia, Hina Gode da Dia Hina Bagade hou sedagilisimu. E amane sia: sa, “Dia ha lai dunu ili ouligima.”
3 Àwọn ènìyàn rẹ jẹ́ ọ̀rẹ́ àtinúwá ní ọjọ́ ìjáde ogun rẹ, nínú ẹwà mímọ́, láti inú òwúrọ̀ wá ìwọ ni ìrì ẹwà rẹ.
Dia ha lai dunuma gegebe eso amoga, Dia fi dunu da hahawane Di fuligala: musa: misunu. Hehebolo mabe galu oubi mogele defele, Dia ayeligi dunu da Di hadigi agologa esalea, amogai Di fidimusa: misunu.
4 Olúwa ti búra, kò sì í yí ọkàn padà pé, “Ìwọ ni àlùfáà, ní ipasẹ̀ Melkisedeki.”
Hina Gode da dafawanedafa ilegele sia: i. Amo E da bu hame afadenemu. E amane sia: i, “Di da Melegisedege gobele salasu dunu ea sosogo fi amo ganodini eso huluanedafa gobele salasu dunu esalumu.”
5 Olúwa, ọwọ́ ọ̀tún rẹ̀ ni yóò lu àwọn ọba bolẹ̀ ni ọjọ́ ìbínú rẹ̀.
Hina Gode da Dia lobodafadili lela. E da ougi heda: sea, osobo bagade hina bagade dunu hasalasimu.
6 Yóò ṣe ìdájọ́ láàrín kèfèrí, yóò kún ibùgbé wọn pẹ̀lú òkú ara; yóò fọ́n àwọn olórí ká sí orí ilẹ̀ ayé tí ó gbòòrò.
E da fifi asi gala huluanema fofada: mu. E da gegesu sogebi amo, bogoi da: i hodo amoga nabalesimu. E da osobo bagade huluane amo ganodini, Hina bagade dunu huluane hasalasimu.
7 Yóò mu nínú odò ṣíṣàn ní ọ̀nà: nítorí náà ni yóò ṣe gbé orí sókè.
Hina Bagade da hano amo logo bega: dalebe, amoga dili manu. Amola amoga gasa laiba: le, E da gasa fili aligili, gegenanu hasalasimu.