< Psalms 11 >
1 Fún adarí orin. Ti Dafidi. Ìgbẹ́kẹ̀lé mi wà nínú Olúwa. Báwo ní ẹ̀yin ó ṣe sọ fún ọkàn mi pé, “Fò gẹ́gẹ́ bi ẹyẹ lọ si orí òkè rẹ.
Hina Gode da na ga: ma: ne, na da dafawaneyale dawa: sa. Di da abuliba: le gogolele nama agoane sia: sala: ?, “Di sioga wa: le ahoabe agoane goumia masa.
2 Wò ó nítorí náà, ènìyàn búburú fa ọfà rẹ̀; wọn ti fi ọfà wọn sí ojú okùn láti tafà níbi òjìji sí àyà ẹni ìdúró ṣinṣin.
Bai wadela: i hamosu dunu ilia oulali amola ilia dadi amo dimagale amola dunu moloidafa gasimigi amoga lelebe gala: musa: amabela: ?
3 Nígbà tí ìpìlẹ̀ bá bàjẹ́ kí ni olódodo yóò ṣe?”
Liligi huluane da mugulusia, dunu noga: i da hahamomu hamedei ba: sa, “Di da abuliba: le agoane sia: sala: ?
4 Olúwa ń bẹ nínú tẹmpili mímọ́ rẹ̀; Olúwa ń bẹ lórí ìtẹ́ rẹ̀ ní ọ̀run. Ó ń wo àwọn ọmọ ènìyàn; ojú rẹ̀ ń yẹ̀ wọ́n wò.
Be Hina Gode da Ea Hadigi Debolo diasu ganodini esala. Amola Ea fafai fisu da Hebene amo ganodini diala. E da soge huluane ganodini, dunu fi huluane ba: lala. Amola ilia adi hamobeale, amo huluane dawa: lala.
5 Olúwa ń yẹ olódodo wò, ṣùgbọ́n ènìyàn búburú àti àwọn tí o fẹ́ ìwà ipá ni ọkàn rẹ̀ kórìíra.
E da noga: i dunu amola wadela: i hamosu dunu defele adoba: sa. Be E da wadela: i hame nabasu dunu amo bagadewane higasa.
6 Sí orí àwọn ènìyàn búburú ni yóò rọ̀jò ẹ̀yín iná àti imí-ọjọ́ tí ń jó; àti ìjì gbígbóná ní yóò jẹ ìpín wọn.
E da wadela: i hamosu dunuma nenowai amola nenanebe salafa sanasisa. E da gia: i bagade fo amoga ilima se iaha.
7 Nítorí, olódodo ní Olúwa, o fẹ́ràn òdodo; ẹni ìdúró ṣinṣin yóò sì rí i.
Hina Gode Ea hou da moloidafa amola E da noga: i hou hamobe amoma asigisa. Nowa da amo hou hamosea, da Ea esalebe gadenene esalumu.