< Psalms 109 >

1 Fún adarí orin. Ti Dafidi. Saamu. Ọlọ́run, ti èmi ń fi ìyìn fún, má ṣe dákẹ́,
Kathutkung: Devit Oe ka pholen e ka Cathut, duem awm hanh.
2 nítorí àwọn ènìyàn búburú àti ẹlẹ́tàn ti ya ẹnu wọn sí mi wọ́n ti fi ahọ́n èké sọ̀rọ̀ sí mi.
Bangkongtetpawiteh, tamikathoutnaw hoi tami kadumyennaw ni, a pahni na ang sin awh teh, lai na thoe sin awh.
3 Wọ́n fi ọ̀rọ̀ ìríra yí mi káàkiri; wọ́n bá mi jà láìnídìí
Hmuhmanae lawk hoi na kalup awh teh, a khuekhaw awm laipalah na tuk awh.
4 Nípò ìfẹ́ mi, wọn ń ṣe ọ̀tá mi, ṣùgbọ́n èmi ń gba àdúrà.
Ka lungpataw e naw teh na katarankung lah a coung awh. Hatei, ratoum laihoi ka o.
5 Wọ́n sì fi ibi san ìre fún mi àti ìríra fún ìfẹ́ mi.
Ahnimouh ni hawinae hah hawihoehnae hoi na patho awh teh, ka pahrennae hah hmuhmanae hoi na patho awh.
6 Yan àwọn ènìyàn búburú láti dojúkọ jẹ́ kí àwọn olùfisùn dúró ní ọwọ́ ọ̀tún rẹ̀.
Ahnimae lathueng vah tamikathoutnaw tat nateh, aranglah vah tarannaw awm naseh.
7 Kí a dá a lẹ́bi nígbà tí a bá ṣe ìdájọ́ kí àdúrà rẹ̀ kí ó lè di ìkọ̀sílẹ̀.
Lawkceng navah sung naseh, a ratoumnae teh yonnae lah coung pouh naseh.
8 Kí ọjọ́ rẹ̀ kí ó kúrú; kí ẹlòmíràn kí ó rọ́pò iṣẹ́ rẹ̀.
A hringnae hnin duem naseh, a thaw teh ayâ alouk ni patawm naseh.
9 Kí àwọn ọmọ rẹ̀ di aláìní baba kí aya rẹ̀ sì di opó.
A canaw teh nara lah awm awh naseh, a yu teh lahmai naseh.
10 Jẹ́ kí àwọn ọmọ rẹ̀ máa ṣagbe kiri kí wọn máa tọrọ oúnjẹ jìnnà sí ibi ahoro wọn.
A canaw teh kâva awh naseh, ka rawk tangcoung e amamae hmuen koehoi rawca tawng awh naseh.
11 Jẹ́ kí alọ́nilọ́wọ́gbà kí ó mú ohun gbogbo tí ó ní jẹ́ kí àlejò kí o kó èrè iṣẹ́ rẹ̀ lọ.
Tangka kacawisaknaw ni a canaw teh laiba dawk lat pouh naseh, a tawk teh a tawn tangcoung e hai apimouh ti panue hoeh e ni koung lat pouh naseh.
12 Má ṣe jẹ́ kí ẹnìkan ṣe àánú fún un tàbí kí wọn káàánú lórí àwọn ọmọ rẹ̀ aláìní baba.
A lathueng vah apinihai lungmanae kamnuek sak hanh naseh. A ca naranaw hai apinihai pahren hanh naseh.
13 Kí a gé àrọ́mọdọ́mọ rẹ̀ kúrò kí orúkọ wọn kí ó parẹ́ ní ìran tí ń bọ̀.
A ca catounnaw hai dout naseh. A catoun awm laipalah a min kahmat naseh.
14 Kí ẹ̀ṣẹ̀ àwọn baba rẹ̀ kí ó wà ní ìrántí ní ọ̀dọ̀ Olúwa. Má ṣe jẹ́ kí a yọ ẹ̀ṣẹ̀ ìyá wọn kúrò.
A na mintoenaw e yonnae teh, BAWIPA hmalah pou pâkuem naseh. A manu yonnae raphoe pouh hanh naseh.
15 Jẹ́ kí ẹ̀ṣẹ̀ wọn kí ó wà ní ìrántí níwájú Olúwa kí ó lè gé ìrántí wọn kúrò lórí ilẹ̀.
Hotnaw teh BAWIPA hmalah pou kamnuek naseh. Het talai van vah, ahnimouh pahnimhoehnae awm hanh naseh.
16 Nítorí kò rántí láti ṣàánú, ṣùgbọ́n ó ṣe inúnibíni sí ọkùnrin tálákà àti olùpọ́njú, kí ó lè pa oníròbìnújẹ́ ọkàn.
Bangkongtetpawiteh, lungmanae kamnue sak hanelah, panuek awh hoeh. A lung ka tangpawk e patenghai a thei thai awh nahanelah, a reikathai hoi mathoenaw hah a pacekpahlek awh.
17 Ó fẹ́ràn láti máa mú ègún wá sí orí rẹ̀: bi inú rẹ̀ kò ti dùn si ìre, bẹ́ẹ̀ ni kí ó jìnnà sí.
Thoe a bo awh e hah amamouh lathueng bawt naseh. Banglahai a noutna awh hoeh e yawhawi ni ahla poungnae koe cettakhai naseh.
18 Bí ó ti fi ègún wọ ará rẹ̀ láṣọ bí ẹ̀wù bẹ́ẹ̀ ni kí ó wá sí inú rẹ̀ bí omi.
Thoebonae hah angki lah a kho e patetlah, a von dawk tui patetlah kâen naseh. A hru thung satui patetlah kâen naseh.
19 Jẹ́ kí ó rí fún un bí aṣọ tí a dà bò ó ní ara, àti fún àmùrè tí ó fi gba ọ̀já nígbà gbogbo.
A kâkhu e hah a khohna patetlah coung naseh, taisawm patetlah a keng dawk pou kâyeng naseh.
20 Èyí ni èrè àwọn ọ̀tá mi láti ọwọ́ Olúwa wá; àti ti àwọn tí ń sọ̀rọ̀ ibi sí ọkàn mi.
Hothateh, ka tarannaw koe BAWIPA ni moipathungnae lah awm naseh. Na pathoe awh dawkvah, a pang awh e lah awm naseh.
21 Ṣùgbọ́n ìwọ, ìwọ ṣe fún mi Olúwa Olódùmarè, ṣe rere fún mi nítorí orúkọ rẹ. Nítorí tí àánú rẹ dára, ìwọ gbà mí.
Hateiteh Oe Bawipa Jehovah, kai hateh na min kecu dawk hawinae hoi na awmkhai haw. Na lungmanae dawkvah, na rungngang haw.
22 Nítorí pé tálákà àti aláìní ni mí, àyà mi sì gbọgbẹ́ nínú mi.
Tami ka roedeng hoi tami ka vout e lah doeh ka o. Ka thung vah ka lungthin teh hmâ a ca.
23 Èmi ń kọjá lọ bí òjìji tí àṣálẹ́, mo ń gbọ̀n sókè bí eṣú.
Kanîka patetlah ka kahma teh, awsi patetlah ka kâhuet.
24 Eékún mi di aláìlera nítorí àwẹ̀ gbígbà ẹran-ara mi sì gbẹ nítorí àìlera mi.
Ka khokpakhu teh rawcahai kecu dawk cak hoeh, ka takthai teh a kamsoe.
25 Mo dàbí ẹ̀gàn fún àwọn olùfisùn mi; nígbà tí wọn wò mí, wọ́n gbọn orí wọn.
Ahnimouh ni na pathoe hanelah ka o teh, na hmu awh toteh lû na saling sin awh.
26 Ràn mí lọ́wọ́, Olúwa Ọlọ́run mi; gbà mí gẹ́gẹ́ bí ìṣeun ìfẹ́ rẹ.
Oe BAWIPA ka Cathut, na kabawm haw. Na lungmanae patetlah na rungngang haw.
27 Jẹ́ kí wọn mọ̀ pé ọwọ́ rẹ ni èyí wí pé ìwọ, Olúwa, ni ó ṣe é.
BAWIPA, hethateh na kut hoi sak e doeh tie a panue thai awh nahanlah.
28 Wọ́n ó máa gégùn ún, ṣùgbọ́n ìwọ máa súre, nígbà tí wọn bá dìde kí ojú kí ó tì wọ́n, ṣùgbọ́n ìránṣẹ́ rẹ yóò yọ̀.
Ahnimouh ni thoe na bo eiteh, nang ni yawhawi na poe haw. Ahnimouh a thaw awh navah kayak awh naseh. Hatei, na san teh konawm naseh.
29 Jẹ́ kí a wọ àwọn ọ̀tá mi ní aṣọ ìtìjú kí á sì fi ìdàrúdàpọ̀ bọ̀ wọ́n lára bí ẹ̀wù.
Na katukkungnaw teh kayanae ni ramuk awh naseh. Min mathoenae hni ni koung ramuk naseh.
30 Pẹ̀lú ẹnu mi èmi yóò máa yin Olúwa gidigidi ní àárín ọ̀pọ̀ ènìyàn èmi yóò máa yìn ín.
Ka pahni hoi BAWIPA teh puenghoi ka pholen han. Bokheiyah, maya hmalah ama teh ka pholen han.
31 Nítorí ó dúró ní apá ọ̀tún aláìní láti gbà á lọ́wọ́ àwọn tí ń dá ọkàn rẹ̀ lẹ́bi.
Bangkongtetpawiteh, yon kapennaw kut dawk hoi rungngang hanelah, ka roedengnaw e aranglah a kangdue han.

< Psalms 109 >