< Psalms 109 >

1 Fún adarí orin. Ti Dafidi. Saamu. Ọlọ́run, ti èmi ń fi ìyìn fún, má ṣe dákẹ́,
Kai ing kam kyih, Aw Khawsa, awi myhna koeh awm hqoeng,
2 nítorí àwọn ènìyàn búburú àti ẹlẹ́tàn ti ya ẹnu wọn sí mi wọ́n ti fi ahọ́n èké sọ̀rọ̀ sí mi.
kawtih thlakchekhqi ingkaw thlak thaikhqi ing amim kha ni ang sih khqi nawh; ami qaai ce kqawn uhy.
3 Wọ́n fi ọ̀rọ̀ ìríra yí mi káàkiri; wọ́n bá mi jà láìnídìí
Sawhnaak awi ing nik chung khqi nawh, akawng a awm kaana ni tuk khqi hy.
4 Nípò ìfẹ́ mi, wọn ń ṣe ọ̀tá mi, ṣùgbọ́n èmi ń gba àdúrà.
Ka pyi na ka taaknaak ce thawlh puknaak na haw law na uhy, cehlai kai taw ak cykcah thlang na awm nyng.
5 Wọ́n sì fi ibi san ìre fún mi àti ìríra fún ìfẹ́ mi.
A leek ce ak che ing thung law unawh, pyi na ka taaknaak cesawhnaak ing thung law uhy.
6 Yan àwọn ènìyàn búburú láti dojúkọ jẹ́ kí àwọn olùfisùn dúró ní ọwọ́ ọ̀tún rẹ̀.
Anih ak oelh aham thlakche ce taak pe tloep; thawlh a pukkung ce ak tang ben awh pha seh.
7 Kí a dá a lẹ́bi nígbà tí a bá ṣe ìdájọ́ kí àdúrà rẹ̀ kí ó lè di ìkọ̀sílẹ̀.
Awideng na a awm awh, dawk lo seitaw, ak cykcahnaak ing dawk sak seh.
8 Kí ọjọ́ rẹ̀ kí ó kúrú; kí ẹlòmíràn kí ó rọ́pò iṣẹ́ rẹ̀.
A hqinglu tawi pe seitaw; thlakchang ing hquikung dyih hun ce qawt pe tloep seh.
9 Kí àwọn ọmọ rẹ̀ di aláìní baba kí aya rẹ̀ sì di opó.
A cakhqi cadah na awm u seitaw a zukhqi nuhai na awm u seh.
10 Jẹ́ kí àwọn ọmọ rẹ̀ máa ṣagbe kiri kí wọn máa tọrọ oúnjẹ jìnnà sí ibi ahoro wọn.
A cakhqi ing kut dun doena van u seitaw; a imqawk awhkawng hqek na awm u seh.
11 Jẹ́ kí alọ́nilọ́wọ́gbà kí ó mú ohun gbogbo tí ó ní jẹ́ kí àlejò kí o kó èrè iṣẹ́ rẹ̀ lọ.
Ik-oeih a capung na ak pukhqi ing a khawhthemkhqi ce lawh pe boeih u seitaw; a bibinaak phu ce khinkhqi ing muk pe bang seh.
12 Má ṣe jẹ́ kí ẹnìkan ṣe àánú fún un tàbí kí wọn káàánú lórí àwọn ọmọ rẹ̀ aláìní baba.
U ingawm koeh qeen seitaw pa amak ta naasenkhqi awm koeh qeen u seh.
13 Kí a gé àrọ́mọdọ́mọ rẹ̀ kúrò kí orúkọ wọn kí ó parẹ́ ní ìran tí ń bọ̀.
A cadil naa ce law boet seitaw, ak law hly kawi chawn awhkaw ming khui awhkawng qeng u seh.
14 Kí ẹ̀ṣẹ̀ àwọn baba rẹ̀ kí ó wà ní ìrántí ní ọ̀dọ̀ Olúwa. Má ṣe jẹ́ kí a yọ ẹ̀ṣẹ̀ ìyá wọn kúrò.
Ami pakhqi thawlhnaak ce Bawipa hai awh sim loet na awm seitaw ami nu a thawlhnaak ce koeh qeng voel seh.
15 Jẹ́ kí ẹ̀ṣẹ̀ wọn kí ó wà ní ìrántí níwájú Olúwa kí ó lè gé ìrántí wọn kúrò lórí ilẹ̀.
Cekkhqi sim loetnaak ce khawmdek awh a law boetnaak aham a mingmih a thawlhnaak ce Bawipa haiawh awm loet seh.
16 Nítorí kò rántí láti ṣàánú, ṣùgbọ́n ó ṣe inúnibíni sí ọkùnrin tálákà àti olùpọ́njú, kí ó lè pa oníròbìnújẹ́ ọkàn.
Ikawtih qeennaak tive poek awm ap poek qoe qoe hy, khawdeng ak voet hlauhkhqi ingkaw kawlung ak kqekkhqi ce him aham hqut hy.
17 Ó fẹ́ràn láti máa mú ègún wá sí orí rẹ̀: bi inú rẹ̀ kò ti dùn si ìre, bẹ́ẹ̀ ni kí ó jìnnà sí.
Lihoei ce lungna hy – amah ak khan awh tla tloep seh; thlang a zoseennaak awh ak kaw am law hy – zoseennaak ce anih a venawh kawng ak hla na awm lawt seh.
18 Bí ó ti fi ègún wọ ará rẹ̀ láṣọ bí ẹ̀wù bẹ́ẹ̀ ni kí ó wá sí inú rẹ̀ bí omi.
Lihoei ce hi na bai nawh; a pum khuiawh tui amyihna kun pehy.
19 Jẹ́ kí ó rí fún un bí aṣọ tí a dà bò ó ní ara, àti fún àmùrè tí ó fi gba ọ̀já nígbà gbogbo.
Ce ing angki amyihna zawl khak seitaw cawi pinnaak amyihna kumqui dy pin seh.
20 Èyí ni èrè àwọn ọ̀tá mi láti ọwọ́ Olúwa wá; àti ti àwọn tí ń sọ̀rọ̀ ibi sí ọkàn mi.
Kai thawlh anik puk khqi ingkaw, kai ak che na anik kqawnkhqi a venawh Bawipa ing ve ve thaphu na pe seh.
21 Ṣùgbọ́n ìwọ, ìwọ ṣe fún mi Olúwa Olódùmarè, ṣe rere fún mi nítorí orúkọ rẹ. Nítorí tí àánú rẹ dára, ìwọ gbà mí.
Cehlai, Aw Boeimang Khawsa, nang ing nang ming ak caming ak leek na ni sai nawh; na lungnaak ak leek ak caming ni hul lah.
22 Nítorí pé tálákà àti aláìní ni mí, àyà mi sì gbọgbẹ́ nínú mi.
Khawdeng ingkaw voethlauh thlang na awm nyng saw, kak kawk khuiawh ak lingbyi ing ngawha ai hy.
23 Èmi ń kọjá lọ bí òjìji tí àṣálẹ́, mo ń gbọ̀n sókè bí eṣú.
Khawmy ben awhkaw khawngkawn amyihna nung thoeih hawh nyng saw; khamkhawk amyihna tlai let let nyng.
24 Eékún mi di aláìlera nítorí àwẹ̀ gbígbà ẹran-ara mi sì gbẹ nítorí àìlera mi.
Buh ka hyhnaak awh kam khawkhlu qawi am cak voel hy; kang sak boeih qep qep nawh a tankqat na awm hqoeng nyng.
25 Mo dàbí ẹ̀gàn fún àwọn olùfisùn mi; nígbà tí wọn wò mí, wọ́n gbọn orí wọn.
Thawlh anik puk khqi ak kqawnseet aham awm kqoeng nyng saw; a mini huh awh ami lu hil uhy.
26 Ràn mí lọ́wọ́, Olúwa Ọlọ́run mi; gbà mí gẹ́gẹ́ bí ìṣeun ìfẹ́ rẹ.
Aw Bawipa ka Khawsa, ni hul lah; na lungnaak ak caming ni hul cang lah.
27 Jẹ́ kí wọn mọ̀ pé ọwọ́ rẹ ni èyí wí pé ìwọ, Olúwa, ni ó ṣe é.
Ve ve nang a kut ni tice sim sak nawh, Aw Bawipa, nang ing ni na sai tice sim sak lah.
28 Wọ́n ó máa gégùn ún, ṣùgbọ́n ìwọ máa súre, nígbà tí wọn bá dìde kí ojú kí ó tì wọ́n, ṣùgbọ́n ìránṣẹ́ rẹ yóò yọ̀.
Cekkhqi ing khawseet hly hlai uhy, nang ingtaw zoseen pe hyk ti; cekkhqi ing ami tuk awh chah phyi kawm uh, cehlai nang a tyihzawih taw zeel kaw.
29 Jẹ́ kí a wọ àwọn ọ̀tá mi ní aṣọ ìtìjú kí á sì fi ìdàrúdàpọ̀ bọ̀ wọ́n lára bí ẹ̀wù.
Kai thawlh anik puk khqi taw ming seetnaak ce hi amyihna bai kawm u saw chahnaak ing angki amyihna zawl qu khoep kawm uh.
30 Pẹ̀lú ẹnu mi èmi yóò máa yin Olúwa gidigidi ní àárín ọ̀pọ̀ ènìyàn èmi yóò máa yìn ín.
Kam kha ing Bawipa ce khawzah na zoeksang kawng nyng saw; thlang kqeng khawzah anglakawh amah kyihcah kawng nyng.
31 Nítorí ó dúró ní apá ọ̀tún aláìní láti gbà á lọ́wọ́ àwọn tí ń dá ọkàn rẹ̀ lẹ́bi.
Ikawtih anik palh sak khqi a venawh kawng anih a hqingnaak ce hul peek aham anih taw ak voethlauhkhqi ak tang ben awh dyi hy.

< Psalms 109 >