< Psalms 109 >

1 Fún adarí orin. Ti Dafidi. Saamu. Ọlọ́run, ti èmi ń fi ìyìn fún, má ṣe dákẹ́,
Katoeng kruek zaehoikung hanah. David ih Saam laa. Ka pakoeh ih, Aw Sithaw, angam duem hmah;
2 nítorí àwọn ènìyàn búburú àti ẹlẹ́tàn ti ya ẹnu wọn sí mi wọ́n ti fi ahọ́n èké sọ̀rọ̀ sí mi.
kasae kaminawk hoi aling thaih kaminawk mah kai han pakha ang angh o thuih, nihcae loe kai khaeah amsawnlok thuih o.
3 Wọ́n fi ọ̀rọ̀ ìríra yí mi káàkiri; wọ́n bá mi jà láìnídìí
Hnukmahaih loknawk hoiah kai ang takui o; takung om ai ah kai ang tuk o.
4 Nípò ìfẹ́ mi, wọn ń ṣe ọ̀tá mi, ṣùgbọ́n èmi ń gba àdúrà.
Kai ih amlunghaih to misa ah a poek o lat; toe kai loe lawkthuihaih hoiah ni ka oh.
5 Wọ́n sì fi ibi san ìre fún mi àti ìríra fún ìfẹ́ mi.
Nihcae mah kahoih hmuen to kasae hoiah ang pathok o moe, kai ih amlunghaih to a hnukma o.
6 Yan àwọn ènìyàn búburú láti dojúkọ jẹ́ kí àwọn olùfisùn dúró ní ọwọ́ ọ̀tún rẹ̀.
To baktih kami nuiah kasae kami to suem pae ah, Setan loe a bantang bangah angdoe pae nasoe.
7 Kí a dá a lẹ́bi nígbà tí a bá ṣe ìdájọ́ kí àdúrà rẹ̀ kí ó lè di ìkọ̀sílẹ̀.
Anih loe lokcaek naah sung nasoe loe, lawk a thuihaih to zaehaih ah angcoeng pae nasoe.
8 Kí ọjọ́ rẹ̀ kí ó kúrú; kí ẹlòmíràn kí ó rọ́pò iṣẹ́ rẹ̀.
A hinghaih aninawk tamsi pae nasoe loe, minawk kalah mah anih angdoethaih ahmuen to la pae ving nasoe.
9 Kí àwọn ọmọ rẹ̀ di aláìní baba kí aya rẹ̀ sì di opó.
Anih ih caanawk loe ampa tawn ai ah om o nasoe loe, a zu loe lamhmai ah om nasoe.
10 Jẹ́ kí àwọn ọmọ rẹ̀ máa ṣagbe kiri kí wọn máa tọrọ oúnjẹ jìnnà sí ibi ahoro wọn.
A caanawk loe ahmuen kruekah amhet hoiah ban patueng o nasoe; kamro a oh o haih im hoiah tacawt o nasoe loe, caaknaek to pakrong o nasoe.
11 Jẹ́ kí alọ́nilọ́wọ́gbà kí ó mú ohun gbogbo tí ó ní jẹ́ kí àlejò kí o kó èrè iṣẹ́ rẹ̀ lọ.
A tawnh ih hmuennawk to hmuenmae coi han paek kami mah la pae boih nasoe; a toksakhaih atho doeh minawk kalah mah lomh pae ving nasoe.
12 Má ṣe jẹ́ kí ẹnìkan ṣe àánú fún un tàbí kí wọn káàánú lórí àwọn ọmọ rẹ̀ aláìní baba.
Mi mah doeh anih nuiah tahmenhaih tawn hmah nasoe; ampa tawn ai nawktanawk doeh tahmen o hmah nasoe.
13 Kí a gé àrọ́mọdọ́mọ rẹ̀ kúrò kí orúkọ wọn kí ó parẹ́ ní ìran tí ń bọ̀.
Anih ih caanawk loe anghma angtaa o nasoe; angzo han koi adungah doeh nihcae ih ahmin to phrae o boih nasoe.
14 Kí ẹ̀ṣẹ̀ àwọn baba rẹ̀ kí ó wà ní ìrántí ní ọ̀dọ̀ Olúwa. Má ṣe jẹ́ kí a yọ ẹ̀ṣẹ̀ ìyá wọn kúrò.
Ampanawk sakpazaehaih loe Angraeng hmaa ah amtueng poe nasoe; amno zaehaih to anghma pae hmah nasoe.
15 Jẹ́ kí ẹ̀ṣẹ̀ wọn kí ó wà ní ìrántí níwájú Olúwa kí ó lè gé ìrántí wọn kúrò lórí ilẹ̀.
Nihcae panoekhaih long hoiah tahmat pae ving hanah, nihcae zaehaih loe Angraeng hmaa ah om poe nasoe.
16 Nítorí kò rántí láti ṣàánú, ṣùgbọ́n ó ṣe inúnibíni sí ọkùnrin tálákà àti olùpọ́njú, kí ó lè pa oníròbìnújẹ́ ọkàn.
Anih loe palungnathaih amtuengsak hanah poek ai, amtang kaminawk to pacaekthlaek moe, palungboeng kaminawk doeh a hum.
17 Ó fẹ́ràn láti máa mú ègún wá sí orí rẹ̀: bi inú rẹ̀ kò ti dùn si ìre, bẹ́ẹ̀ ni kí ó jìnnà sí.
Anih loe tangoenghaih to palung pongah, tangoenghaih to anih nuiah krah nasoe; tahamhoihaih koeh ai pongah, tahamhoihaih loe anih khae hoi kangthla ah om nasoe.
18 Bí ó ti fi ègún wọ ará rẹ̀ láṣọ bí ẹ̀wù bẹ́ẹ̀ ni kí ó wá sí inú rẹ̀ bí omi.
Anih mah loksae to kahni baktiah angkhuk pongah, a zok thungah tui baktih, ahuhnawk thungah situi baktiah akun pae nasoe.
19 Jẹ́ kí ó rí fún un bí aṣọ tí a dà bò ó ní ara, àti fún àmùrè tí ó fi gba ọ̀já nígbà gbogbo.
Angmah angkhuk ih kahni baktih, kaengah angzaeng poe ih kazii baktiah, a nuiah om pae nasoe.
20 Èyí ni èrè àwọn ọ̀tá mi láti ọwọ́ Olúwa wá; àti ti àwọn tí ń sọ̀rọ̀ ibi sí ọkàn mi.
Kai kasaethui kaminawk khaeah, Angraeng mah hae hae tangqum ah paek nasoe.
21 Ṣùgbọ́n ìwọ, ìwọ ṣe fún mi Olúwa Olódùmarè, ṣe rere fún mi nítorí orúkọ rẹ. Nítorí tí àánú rẹ dára, ìwọ gbà mí.
Toe, Aw Angraeng Sithaw, na hmin hoiah na sah paeh; na palungnathaih loe hoih pongah, na pahlong ah.
22 Nítorí pé tálákà àti aláìní ni mí, àyà mi sì gbọgbẹ́ nínú mi.
Kai loe kam tang, ka tak thung ih palung loe ahma caak boeh.
23 Èmi ń kọjá lọ bí òjìji tí àṣálẹ́, mo ń gbọ̀n sókè bí eṣú.
Kai loe duembang ih tahlip baktiah ka zaem tathuk boeh; pakhuh baktiah ahnuk ahma kang thuih.
24 Eékún mi di aláìlera nítorí àwẹ̀ gbígbà ẹran-ara mi sì gbẹ nítorí àìlera mi.
Buhzah pongah ka khokkhunawk hae cak ai boeh; ka taksa doeh zaek keng boeh.
25 Mo dàbí ẹ̀gàn fún àwọn olùfisùn mi; nígbà tí wọn wò mí, wọ́n gbọn orí wọn.
Minawk kasaethuih han ih ni ka oh boeh moe, nihcae mah kai ang khet o naah lu ang haek o thuih.
26 Ràn mí lọ́wọ́, Olúwa Ọlọ́run mi; gbà mí gẹ́gẹ́ bí ìṣeun ìfẹ́ rẹ.
Aw Angraeng ka Sithaw, na bom ah; na palungnathaih hoiah na pahlong ah,
27 Jẹ́ kí wọn mọ̀ pé ọwọ́ rẹ ni èyí wí pé ìwọ, Olúwa, ni ó ṣe é.
hae loe na ban ni; Angraeng, nang mah ni na sak, tiah panoek o nasoe.
28 Wọ́n ó máa gégùn ún, ṣùgbọ́n ìwọ máa súre, nígbà tí wọn bá dìde kí ojú kí ó tì wọ́n, ṣùgbọ́n ìránṣẹ́ rẹ yóò yọ̀.
Nihcae loe tangoeng o, toe nang loe tahamhoihaih paek ah; nihcae angthawk o naah, azat o nasoe; toe na tamna loe anghoe nasoe.
29 Jẹ́ kí a wọ àwọn ọ̀tá mi ní aṣọ ìtìjú kí á sì fi ìdàrúdàpọ̀ bọ̀ wọ́n lára bí ẹ̀wù.
Ka misanawk loe azathaih to kahni baktiah angkhuk o nasoe, kahni hoi khuk ih baktiah, mikhmai sethaih to angkhuk o nasoe.
30 Pẹ̀lú ẹnu mi èmi yóò máa yin Olúwa gidigidi ní àárín ọ̀pọ̀ ènìyàn èmi yóò máa yìn ín.
Ka pakha hoiah Angraeng to ka pakoeh parai boeh; ue, pop parai salakah anih to ka pakoeh han.
31 Nítorí ó dúró ní apá ọ̀tún aláìní láti gbà á lọ́wọ́ àwọn tí ń dá ọkàn rẹ̀ lẹ́bi.
Zaehaih net kaminawk ih ban thung hoiah amtang kaminawk ih hinghaih pahlong hanah, anih loe amtang kaminawk ih bantang bangah angdoet.

< Psalms 109 >