< Psalms 108 >

1 Orin. Saamu ti Dafidi. Ọlọ́run, ọkàn mi dúró ṣinṣin èmi ó máa kọrin, èmi ó máa fi ọkàn mi kọrin.
Thaburi ya Daudi Wee Ngai, ngoro yakwa nĩĩkindĩirie; nĩkũina ngũina, ngũgooce na rwĩmbo na muoyo wakwa wothe.
2 Jí ohun èlò orin àti haapu! Èmi ó jí ní kùtùkùtù,
Arahũka, wee kĩnanda kĩa mũgeeto na gĩa kĩnũbi! Ngwarahũka ruoro rũgĩtema.
3 èmi ó yìn ọ́, Olúwa, nínú àwọn orílẹ̀-èdè, èmi ó kọrin rẹ nínú àwọn ènìyàn.
Wee Jehova nĩngũkũgooca, ngũgooce gatagatĩ-inĩ ka ndũrĩrĩ; nĩngũkũinĩra ndĩ gatagatĩ-inĩ ka andũ.
4 Nítorí tí o tóbi ní àánú rẹ ju àwọn ọ̀run lọ àti òdodo rẹ dé àwọsánmọ̀.
Nĩgũkorwo wendo waku nĩ mũnene, ũkaraiha gũkĩra igũrũ; wĩhokeku waku ũkinyaga o matu-inĩ.
5 Gbé ara rẹ ga, Ọlọ́run, lórí àwọn ọ̀run, àti ògo rẹ lórí gbogbo ayé.
Wee Ngai tũũgĩra, ũtũũgĩrio igũrũ rĩa igũrũ, riiri waku nĩũgĩe igũrũ rĩa thĩ yothe.
6 Kí a sì lè gba àwọn olùfẹ́ rẹ là; fi ọwọ́ ọ̀tún rẹ ṣe ìgbàlà, kí o sì dá mi lóhùn
Tũhonokie na ũtũteithie na guoko gwaku kwa ũrĩo, nĩguo ũteithũre arĩa wendete.
7 Ọlọ́run ti sọ̀rọ̀ láti ibi mímọ́ rẹ̀ pé, “Èmi yóò yọ̀, èmi yóò pín Ṣekemu, èmi yóò sì wọn àfonífojì Sukkoti kúrò.
Ngai nĩarĩtie arĩ handũ hake harĩa haamũre, akoiga atĩrĩ: “Nĩngatũranga Shekemu ndĩ na gĩkeno kĩingĩ, na thimĩre andũ akwa Gĩtuamba gĩa Sukothu.
8 Gileadi ni tèmi, Manase ni tèmi, Efraimu ni ìbòrí mi, Juda ni olófin mi,
Gileadi nĩ gwakwa, o na Manase no gwakwa; Efiraimu nĩ ngũbia yakwa ya kĩgera, na Juda nĩ mũthĩgi wakwa wa ũthamaki.
9 Moabu sì ni ìkòkò ìwẹsẹ̀ mi, lórí Edomu ni èmi ó bọ́ bàtà mi sí, lórí òkè Filistia ni èmi yóò hó ìhó ayọ̀.”
Moabi nĩ kĩraĩ gĩakwa gĩa gwĩthambĩra, na Edomu nĩho njikagia kĩraatũ gĩakwa; nĩngwanĩrĩra nĩ ũrĩa ndooretie bũrũri wa Filistia.”
10 Ta ni yóò mú mi wá sí ìlú olódi? Ta ni yóò sìn mí wá sí Edomu?
Nũũ ũkũnginyia itũũra rĩrĩa inene rĩirigĩre? Nũũ ũkũndongoria andware Edomu?
11 Ìwọ Ọlọ́run ha kọ́, ìwọ tí ó ti kọ̀ wá sílẹ̀. Ọlọ́run ìwọ kì yóò bá àwọn jagunjagun wa jáde mọ́.
Githĩ tiwe, Wee Ngai, o Wee ũtũtiganĩirie, na ũgatiga gũtwarana na mbũtũ ciitũ cia ita?
12 Fún wa ní ìrànlọ́wọ́ nínú ìpọ́njú, nítorí ìrànlọ́wọ́ ènìyàn asán ni.
Tũteithie ũtũhootanĩre harĩ thũ ciitũ, nĩgũkorwo ũteithio wa mũndũ nĩ wa tũhũ.
13 Nípasẹ̀ Ọlọ́run ni àwa ó ṣe akin nítorí òun ó tẹ àwọn ọ̀tá wa mọ́lẹ̀.
Ngai arĩ hamwe na ithuĩ nĩtũkũhootana, na nĩakarangĩrĩria thũ ciitũ thĩ.

< Psalms 108 >